Publicidade

Marcos 10

Ìkọ̀sílẹ̀

1 10.1-12: Mt 19.1-9. 10.1: Lk 9.51; Jh 10.40; 11.7. Nígbà náà, Jesu kúrò níbẹ̀, ó ẹkùn Judea níhà òkè odò Jordani. Àwọn ènìyàn tún tọ̀ ́ , i ìṣe rẹ̀, ó kọ́ wọn.

2 Àwọn Farisi kan tọ̀ ́ , láti dán an . Wọ́n béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ , "Ǹjẹ́ ó ha tọ̀fún ènìyàn láti kọ ìyàwó rẹ̀ sílẹ̀?"

3 Jesu béèrè lọ́wọ́ wọn , "ni Mose pàṣẹ fún un yín?"

4 10.4: De 24.1-4. Wọ́n dáhùn , "Mose yọ̀ǹda fún wa láti kọ ìwé ìkọ̀sílẹ̀ fún un, a fi sílẹ̀."

5 Ṣùgbọ́n Jesu wọn lóhùn, ó , "Nítorí líle àyà yín ni Mose fi kọ òfin yìí fun un yín. 6 10.6: Gẹ 1.27; 5.2.Ṣùgbọ́n láti ìgbà ayé ti ṣẹ̀, Ọlọ́run wọn akọ àti abo. 7 10.7-8: Gẹ 2.24.Nítorí ìdí èyí, ọkùnrin yóò fi baba àti ìyá rẹ̀ sílẹ̀ yóò fi ara mọ́ aya rẹ̀. 8 Òun àti ìyàwó rẹ̀ yóò di ara kan náà. Nítorí náà, wọn í túnṣe méjì mọ́ ṣe ẹyọ ̀kan ṣoṣo. 9 Nítorí náà ohun ti Ọlọ́run sọ dọ̀kan, ki ẹnikẹ́ni máa ṣe wọ́n."

10 Lẹ́yìn náà, nígbà Jesu nìkan nínú ilé pẹ̀àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, wọ́n tún béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ nípa ohun kan náà. 11 10.11: Mt 5.32; Lk 16.18; 1Kọ 7.10-11; Ro 7.2-3.Jesu túbọ̀ ṣe àlàyé fún wọn , "Ẹnikẹ́ni ó kọ aya rẹ̀ sílẹ̀ ó fẹ́ ẹlòmíràn, irú ọkùnrin bẹ́̀ ṣe panṣágà obìnrin ó ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé níyàwó. 12 Bẹ́̀ gẹ́gẹ́, obìnrin kan kọ ọkọ rẹ̀ sílẹ̀ ó fẹ́ ọkùnrin mìíràn, irú obìnrin bẹ́̀ ṣe panṣágà."

Jesu àti àwọn ọmọdé

13 10.13-16: Mt 19.13-15; 18.3; Lk 18.15-17. Lẹ́yìn èyí, àwọn ènìyàn bẹ̀rẹ̀ í gbé àwọn ọmọ wẹ́wẹ́ tọ Jesu ó súre fún wọn. Ṣùgbọ́n àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ kígbe mọ́ àwọn ń gbé àwọn ọmọdé wọ̀nyí bọ̀ wọn gbọdọ̀ yọ Jesu lẹ́nu rárá. 14 Ṣùgbọ́n nígbà Jesu ohun ó ń ṣẹlẹ̀, inú rẹ̀ dùn àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀. Nítorí náà, ó sọ fún wọn , "jẹ́ àwọn ọmọdé kékeré sọ́dọ̀ mi. ṣe wọn lẹ́kun nítorí irú wọn ni ìjọba Ọlọ́run. 15 Lóòótọ́ ni mo fún yín, ẹnikẹ́ni gba ìjọba Ọlọ́run ọmọ kékeré, yóò le è wọ inú rẹ̀." 16 10.16: Mk 9.36.Nígbà náà, Jesu gbé àwọn ọmọ náà ọwọ́ rẹ̀, ó gbé ọwọ́ orí wọn. Ó súre fún wọn.

̀dọ́mọkùnrin ọlọ́rọ̀

17 10.17-31: Mt 19.16-30; Lk 18.18-30. 10.17: Lk 10.25; Mk 1.40. Jesu ti bẹ̀rẹ̀ ìrìnàjò rẹ, ọkùnrin kan sáré sọ́dọ̀ rẹ̀. Ó kúnlẹ̀, ó béèrè , "Olùkọ́ rere, ni èmi yóò ṣe láti jogún ìyè àìnípẹ̀kun?"

18 Jesu béèrè , arákùnrin, "Èéṣe o fi ń ẹni rere? Ẹni rere kan Ọlọ́run nìkan ni ẹni rere. 19 10.19: Ek 20.12-16; De 5.16-20.Ìwọ mọ àwọn òfin : Ìwọ gbọdọ̀ pànìyàn, ìwọ gbọdọ̀ ṣe panṣágà, ìwọ gbọdọ̀ jalè, ìwọ gbọdọ̀ purọ́, ìwọ gbọdọ̀ rẹ́ ọmọnìkejì jẹ, bọ̀wọ̀ fún baba àti ìyá rẹ.’ "

20 Ọkùnrin náà dáhùn , "Olùkọ́, gbogbo nǹkan wọ̀nyí ni èmi ń ṣe láti ìgbà èwe mi ."

21 10.21: Mt 6.20; Lk 12.33; Ap 2.45; 4.34-35. Jesu ó tìfẹ́tìfẹ́. Ó fún un , "ó bẹ́̀, ohun kan fún láti ṣe, lọ nísinsin yìí, ta gbogbo nǹkan o , o pín owó náà fún àwọn aláìní ìwọ yóò ìṣúra ̀run, , ó máa tọ̀ lẹ́yìn."

22 Nígbà ọkùnrin yìí gbọ́ èyí, ojú rẹ̀ korò, ó lọ pẹ̀ìbànújẹ́, nítorí ó ọrọ̀ púpọ̀.

23 Jesu ó ọkùnrin náà ti ń lọ. Ó yípadà, ó sọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ , "Àní, ohun ìṣòro ni fún ọlọ́rọ̀ láti wọ ìjọba Ọlọ́run!"

24 ̀rọ̀ yìí ya àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ lẹ́nu. Jesu tún sọ fún wọn , "Ẹyin ọmọ yóò ṣòro fún àwọn ó ìgbẹ́kẹ̀nínú ọrọ̀ láti wọ ìjọba Ọlọ́run. 25 Ó rọrùn fún ìbákasẹ láti gba ojú abẹ́rẹ́ wọlé fún ọlọ́rọ̀ kan láti wọ ìjọba ̀run."

26 Ẹnu túbọ̀ ya àwọn ọmọ-ẹ̀yìn i. Wọ́n béèrè , "ó bẹ́̀, ta ni nínú ayé ni ó ìgbàlà?"

27 Jesu wọ́n, ó fún wọn , "Ènìyàn èyí ṣe é ṣe fún ṣùgbọ́n í ṣe fún Ọlọ́run, nítorí ohun gbogbo ni ṣíṣe fún Ọlọ́run."

28 10.28: Mk 1.16-20. Nígbà náà ni Peteru kọjú Jesu, ó , "Àwa ti fi ohun gbogbo sílẹ̀, a ń tọ̀ ́ lẹ́yìn."

29 Jesu dáhùn , "Lóòótọ́ ni mo fún un yín , ẹnikẹ́ni ó fi ohunkóhun sílẹ̀ : ilé, tàbí àwọn arákùnrin, tàbí àwọn arábìnrin, tàbí ìyá, tàbí baba, tàbí àwọn ọmọ tàbí ohun ìní nítorí mi àti nítorí ìyìnrere, 30 10.30: Mt 6.33.a yóò fún padà ọgọọgọ́rùn-ún àwọn ilé, tàbí arákùnrin, tàbí arábìnrin, tàbí ìyá, tàbí ọmọ, tàbí ilẹ̀, àti inúnibíni pẹ̀. Gbogbo nǹkan wọ̀nyí yóò jẹ́ tirẹ̀ ayé yìí àti ayé ń bọ̀ yóò ìyè àìnípẹ̀kun. 31 10.31: Mt 20.16; Lk 13.30.Ṣùgbọ́n ̀pọ̀ àwọn ó síwájú ni yóò di ẹni ìkẹyìn, àwọn ó kẹ́yìn yóò síwájú."

Jesu tún sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa ikú ara rẹ̀

32 10.32-34: Mt 20.17-19; Lk 18.31-34. Nísinsin yìí, wọ́n lójú ̀Jerusalẹmu. Jesu ń lọ níwájú wọn, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn ti ń tẹ̀e, ìbẹ̀kún ọkàn wọn. Ó tún àwọn méjìlá apá kan, ó bẹ̀rẹ̀ ṣàlàyé ohun gbogbo a ó ṣe i fún wọn. 33 10.33: Mk 8.31; 9.12; 9.33.Ó sọ fún wọn , "Àwa ń gòkè lọ Jerusalẹmu, a ó fi Ọmọ Ènìyàn àwọn olórí àlùfáà àti àwọn olùkọ́ òfin lọ́wọ́. Wọn ni yóò lẹ́bi ikú. Wọn yóò á ọwọ́ àwọn aláìkọlà. 34 10.34: Mk 14.65; 15.19,26-32.Wọn yóò fi ṣe ẹlẹ́, wọn yóò tutọ́ ara, wọn yóò pẹ̀pàṣán wọn. Wọn yóò pa, ṣùgbọ́n lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́ta yóò tún jíǹde."

Ìbéèrè Johanu àti Jakọbu

35 10.35-45: Mt 20.20-28. Lẹ́yìn èyí, Jakọbu àti Johanu, àwọn ọmọ Sebede sọ́dọ̀ Jesu. Wọ́n a sọ̀rọ̀ kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́, wọ́n , "Olùkọ́, inú wa yóò dùn ìwọ ṣe ohunkóhun a béèrè fún wa."

36 Jesu béèrè , "ni ̀yin ń fẹ́ èmi ó ṣe fún un yín?"

37 10.37: Mt 19.28; Lk 22.30. Wọ́n bẹ̀bẹ̀ , "Jẹ́ ̀kan nínú wa jókòó ọwọ́ ̀tún rẹ àti ẹnìkejì ọwọ́ òsì nínú ògo rẹ!"

38 10.38: Lk 12.50; Jh 18.11. Ṣùgbọ́n Jesu wọn lóhùn , "mọ ohun ̀ ń béèrè! Ṣe mu nínú ago kíkorò èmi ó tàbí a bamitiisi yín pẹ̀irú ì bamitiisi ìjìyà a ó fi bamitiisi mi?"

39 10.39: Ap 12.2; If 1.9. Àwọn méjèèjì dáhùn , "Àwa pẹ̀ṣe bẹ́̀."

Jesu fún wọn , "Lóòótọ́ ni ̀yin ó mu ago ti èmi yóò mu, àti bamitiisi a bamitiisi mi ni a ó fi bamitiisi yín, 40 ṣùgbọ́n láti jókòó ọwọ́ ̀tún mi àti ọwọ́ òsì mi ì ṣe ti èmi láti fi fún ni: ṣe fún àwọn ẹni a ti pèsè rẹ̀ sílẹ̀ fún."

41 Nígbà àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mẹ́wàá ìyókù gbọ́ ohun Jakọbu àti Johanu béèrè, wọ́n bínú. 42 10.42-45: Lk 22.25-27.Nítorí ìdí èyí, Jesu wọ́n sọ́dọ̀, ó fún wọn , "Gẹ́gẹ́ ̀yin ti mọ̀ , àwọn ọba àti àwọn kèfèrí ń lo agbára lórí àwọn ènìyàn. 43 10.43: Mk 9.35.Ṣùgbọ́n láàrín yín ko gbọdọ̀ ri bẹ. Ẹnikẹ́ni ó fẹ́ di olórí nínú yín gbọdọ̀ ṣe ìránṣẹ́. 44 Ẹnikẹ́ni ó fẹ́ di aṣáájú nínú yín gbọdọ̀ ṣe ìránṣẹ́ gbogbo yín. 45 10.45: 1Tm 2.5-6.Nítorí, Èmi, Ọmọ Ènìyàn ayé ṣe ìránṣẹ́ fún mi, ṣùgbọ́n láti ṣe ìránṣẹ́ fun àwọn ẹlòmíràn, àti láti fi ̀rẹ̀ ṣe ìràpadà ̀pọ̀ ènìyàn." 46 10.46-52: Mt 20.29-34; Lk 18.35-43; Mk 8.22-26.Wọ́n Jeriko, Jesu àti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ àti ̀pọ̀ ènìyàn ti fẹ́ kúrò ìlú Jeriko, ọkùnrin afọ́kan, Bartimeu, ọmọ Timeu jókòó lẹ́gbẹ̀́ ̀ó ń ṣagbe.

Bartimeu afọ́gba ìwòsàn

47 10.47: Mt 9.27. Nígbà Bartimeu gbọ́ Jesu ti Nasareti nítòsí, o bẹ̀rẹ̀ kígbe lóhùn rara , "Jesu ọmọ Dafidi, ṣàánú fún mi."

48 Àwọn níbẹ̀ kígbe mọ́ ọn , "Pa ẹnu rẹ mọ́." Ṣùgbọ́n dípò ó pa ẹnu mọ́, ṣe ń kígbe lóhùn rara , "Jesu ọmọ Dafidi ṣàánú fún mi."

49 Nígbà Jesu gbọ́ igbe rẹ̀, ó dẹ́sẹ̀ dúró lójú ̀, ó , "é ó sọ́dọ̀ mi."

Nítorí náà wọ́n pe ọkùnrin afọ́náà, wọ́n , "Tújúká! Dìde lórí ẹsẹ̀ rẹ! Ó ń ́." 50 Lẹ́sẹ̀kan náà, Bartimeu bọ́ agbádá rẹ̀ sọnù, ó sókè, ó sọ́dọ̀ Jesu.

51 Jesu béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ , "ni ìwọ fẹ́ èmi ó ṣe fún ?"

Afọ́náà dáhùn , "Rabbi, jẹ́ èmi ó ríran."

52 10.52: Mt 9.22; Mk 5.34; Lk 7.50; 8.48; 17.19. Jesu fún un , "Máa lọ, ìgbàgbọ́ rẹ ti láradá." Lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀, ọkùnrin afọ́náà ríran ó ń tẹ̀Jesu lọ ̀.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-