Publicidade

Marcos 2

Jesu wo aláàrùn ̀gbà sàn

1 Lẹ́yìn ọjọ́ mélòó kan, nígbà Jesu tún padà wọ Kapernaumu, òkìkí kàn ó ti nínú ilé. 2 Láìpẹ́, ogunlọ́gọ̀ ènìyàn ti kún ilé ó bẹ́̀ inú ilé àti ̀yìn ìlẹ̀kùn ìta gba ẹyọ ẹnìkan mọ́, ó wàásù ̀rọ̀ náà wọn. 3 2.3-12: Mt 9.2-8; Lk 5.18-26.Àwọn ọkùnrin kan , wọ́n gbé arọ tọ̀ ́ , ẹni ọkùnrin mẹ́rin gbé. 4 Nígbà wọn le ̀dọ̀ Jesu, nítorí ̀pọ̀ ènìyàn, wọ́n òrùlé ilé lu ̀gangan ibi Jesu . Wọ́n sọ ọkùnrin arọ náà kalẹ̀ ti òun ti àkéte rẹ̀ níwájú Jesu. 5 Nígbà Jesu ìgbàgbọ́ wọn, ó sọ fún arọ náà , "Ọmọ, a dárí gbogbo ̀ṣẹ̀ rẹ ́."

6 Ṣùgbọ́n díẹ̀ nínú àwọn olùkọ́ òfin jókòó níbẹ̀ sọ fún ara wọn , 7 "Èéṣe ti ọkùnrin yìí fi sọ̀rọ̀ báyìí? Ó ń sọ̀rọ̀-òdì. Ta ni ó darí ̀ṣẹ̀ ji ni ko ṣe Ọlọ́run nìkan?"

8 Lójúkan náà Jesu wòye nínú ọkàn rẹ̀ wọn ń gbèrò bẹ́̀ àárín ara wọn, ó fún wọn , "Èéṣe ̀yìn fi ń ro nǹkan wọ̀nyí nínú ọkàn yín? 9 Èwo ni ó rọrùn láti fún arọ náà , A dárí ̀ṣẹ̀ rẹ̀ ,tàbí , Dìde gbé àkéte rẹ, o máa rìn? 10 Ṣùgbọ́n mọ̀ Ọmọ Ènìyàn agbára ayé láti dárí ̀ṣẹ̀ rẹ̀ ji ni." Ó fún ọkùnrin arọ náà , 11 "Mo fún , dìde, gbé àkéte rẹ ó máa lọ ilé rẹ." 12 2.12: Mt 9.33.Lójúkan náà, ọkùnrin náà sókè fún ayọ̀. Ó gbé àkéte rẹ̀. Ó jáde lọ lójú gbogbo wọn. Èyí ya gbogbo wọn lẹ́nu bẹ́̀ wọ́n yin Ọlọ́run lógo , "Àwa irú èyí !"

Ìpè Lefi

13 Nígbà náà, Jesu tún jáde lọ etí Òkun. ̀pọ̀ ènìyàn tọ̀ ́ , ó bẹ̀rẹ̀ kọ́ wọn. 14 2.14-17: Mt 9.9-13; Lk 5.27-32.ó ti ń rin etí Òkun lọ sókè, ó Lefi ọmọ Alfeu ó jókòó nínú àgọ́ níbi ó ti ń gba owó orí, Jesu fún un , "Tẹ̀mi," Lefi dìde, ó ń tẹ̀e.

15 Ó ṣe, ó ti jókòó ti oúnjẹ ni ilé Lefi, ̀pọ̀ àwọn agbowó òde àti ẹlẹ́ṣẹ̀ Jesu jókòó pẹ̀àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, nítorí tiwọn pọ̀ tiwọn tẹ̀e. 16 2.16: Ap 23.9.Nígbà àwọn olùkọ́ òfin àti àwọn Farisi ì ó ń àwọn agbowó òde àti àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ jẹun, wọn fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ , "Èétirí ó fi ń àwọn agbowó òde àti ẹlẹ́ṣẹ̀ jẹun?"

17 Nígbà Jesu gbọ́, ó sọ fún wọn , "Àwọn ara wọ́n wa oníṣègùn, ko ṣe àwọn ara wọn . Èmi láti sọ fún àwọn ènìyàn rere láti ronúpìwàdà, ṣe àwọn ènìyàn ẹlẹ́ṣẹ̀."

Ìbéèrè nípa àwẹ̀ lọ́wọ́ Jesu

18 2.18-22: Mt 9.14-17; Lk 5.33-38. Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Johanu àti àwọn Farisi a máa gbààwẹ̀. Àwọn ènìyàn kan , wọ́n bi í , "Èéṣe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Johanu àti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Farisi fi ń gbààwẹ̀, ṣùgbọ́n àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ gbààwẹ̀?"

19 Jesu dáhùn , "Báwo ni àwọn àlejò ọkọ ìyàwó yóò ṣe máa gbààwẹ̀ nígbà ọkọ ìyàwó ṣì lọ́dọ̀ wọn? 20 2.20: Lk 17.22.Ṣùgbọ́n láìpẹ́ ọjọ́, a ó gba ọkọ ìyàwó kúrò lọ́dọ̀ wọn. Nígbà náà wọn yóò gbààwẹ̀ ni ọjọ́ wọ̀nyí."

21 "ẹni ń fi ìrépé aṣọ tuntun lẹ ògbólógbòó ̀, ó ba ṣe bẹ́̀, èyí tuntun a fi lẹ̀ ́ yóò fàya kúrò lára ògbólógbòó, yíya rẹ̀ yóò burú púpọ̀ . 22 ẹni ń fi ọtí wáìnì tuntun sínú ìgò wáìnì ògbólógbòó. a ṣe bẹ́̀, ọtí wáìnì náà yóò fa ìgò náà ya, ọtí wáìnì a dàànù, bákan náà ni ìgò náà, ṣùgbọ́n ọtí wáìnì tuntun ni a n fi sínú ìgò wáìnì tuntun."

Olúwa ọjọ́ ìsinmi

23 2.23-28: Mt 12.1-8; Lk 6.1-5. 2.23: De 23.25. Ó ṣe ni ọjọ́ ìsinmi, Jesu àti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ti ń kọjá lọ láàrín oko ọkà, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ í ya ìpẹ́ ọkà. 24 Díẹ̀ nínú àwọn Farisi fún Jesu , "ó, èéṣe tiwọn fi ń ṣe èyí ti yẹ ni ọjọ́ ìsinmi."

25 Ó wọn lóhùn , "̀yin ti ka ohun Dafidi ṣe, nígbà ó ṣe aláìní, ebi ń pa á, òun àti àwọn ó lọ́dọ̀ rẹ̀? 26 2.26: 1Sa 21.1-6; 2Sa 8.17.ó wọ ilé Ọlọ́run lọ ni ọjọ́ Abiatari olórí àlùfáà, ó jẹ àkàrà ìfihàn ti tọ́ fún un láti jẹ ṣe fún àwọn àlùfáà, ó tún fi fún àwọn ń bẹ lọ́dọ̀ rẹ̀."

27 2.27: Ek 23.12; De 5.14. Ó fún wọ́n , a ọjọ́ ìsinmi fún ènìyàn, "Ṣùgbọ́n a ènìyàn fún ọjọ́ ìsinmi. 28 Nítorí náà Ọmọ Ènìyàn ni Olúwa ọjọ́ ìsinmi pẹ̀."

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_21-26-40-