Pular para o conteúdo
Publicidade

Marcos 3

1 3.1-6: Mt 12.9-14; Lk 6.6-11. Nígbà Jesu Sinagọgu. kíyèsi i ọkùnrin kan níbẹ̀, ọwọ́ rẹ̀ kan rọ. 2 3.2: Lk 11.54.Àwọn kan nínú wọn ń wa ̀láti fi ̀sùn kan Jesu. Nítorí náà, wọ́n ń ṣọ́ yóò un láradá ọjọ́ ìsinmi. 3 Jesu fún ọkùnrin ọwọ́ rẹ̀ rọ náà , "Dìde dúró iwájú ìjọ ènìyàn."

4 Nígbà náà ni Jesu béèrè lọ́wọ́ wọn , "Ǹjẹ́ ó òfin mu ọjọ́ ìsinmi bóyá láti ṣe rere, tàbí láti ṣe búburú! Láti gbà ̀, tàbí pa á run?" Ṣùgbọ́n wọ́n dákẹ́ láìfèsì.

5 Nígbà ó wo gbogbo wọn yíká pẹ̀ìbínú, ọkàn rẹ̀ bàjẹ́ nítorí líle àyà wọn, ó sọ fún ọkùnrin náà , "Na ọwọ́ rẹ jáde." Ó án jáde, ọwọ́ náà bọ̀ sípò padà pátápátá. 6 3.6: Mk 12.13.Lójúkan náà, àwọn Farisi jáde lọ, láti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Herodu gbìmọ̀ pọ̀, wọn yóò ṣe pa Jesu.

̀pọ̀ ènìyàn tẹ̀Jesu

7 3.7-12: Mt 4.24-25; 12.15-16; Lk 6.17-19. Jesu pẹ̀àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ yẹra kúrò níbẹ̀ lọ etí Òkun. ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn láti Galili àti Judea tọ̀ ́ lẹ́yìn. 8 3.8: Mt 11.21.Nígbà wọ́n gbọ́ ìròyìn iṣẹ́ ìyanu ó ṣe, ̀pọ̀ ènìyàn tọ̀ ́ láti Judea, Jerusalẹmu àti Idumea, àti láti apá kejì odò Jordani àti láti ìhà Tire àti Sidoni. 9 Nítorí ̀pọ̀ ènìyàn, Jesu sọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ láti ṣètò ọkọ̀ ojú omi kékeré kan sílẹ̀ fún un láti lọ, láti àwọn èrò sẹ́yìn. 10 3.10: Mk 5.29,34; 6.56.Nítorí ó ̀pọ̀ ènìyàn láradá, ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn aláìsàn ara wọn ú láti fi ọwọ́ kàn án. 11 Ìgbàkúgbà àwọn ó ni ̀àìmọ́ ti fojú ri, wọ́n á wólẹ̀ níwájú rẹ̀. Wọn a kígbe lóhùn rara , "Ìwọ ni Ọmọ Ọlọ́run." 12 3.12: Mk 1.45.Ṣùgbọ́n ó kìlọ̀ fún wọn gidigidi, wọn ṣe fi òun hàn.

Jesu yan àwọn aposteli méjìlá

13 3.13: Mt 5.1; Lk 6.12. Jesu gun orí òkè lọ, ó pe àwọn kan ó yàn láti pẹ̀rẹ̀, wọ́n tọ̀ ́ . 14 Ó yan àwọn méjìlá, wọn ó pẹ̀rẹ̀, àti ó rán wọn lọ láti wàásù 15 àti láti lágbára láti àwọn ̀Èṣù jáde.

16 3.16-19: Mt 10.2-4; Lk 6.14-16; Ap 1.13. Wọ̀nyí ni àwọn méjìlá náà ó yàn:

Simoni (ẹni ti ó sọ àpèlé rẹ̀ Peteru),

17 Jakọbu ọmọ Sebede àti Johanu arákùnrin rẹ̀ (àwọn ẹni Jesu sọ àpèlé wọ́n Boanaji, èyí ó túmọ̀ "àwọn ọmọ àrá").

18 Àti Anderu,

Filipi,

Bartolomeu,

Matiu,

Tomasi,

Jakọbu ọmọ Alfeu,

Taddeu,

Simoni ń jẹ́ Sealoti 3.18 Ọ̀kan nínú àwọn ẹgbẹ́ tí o ń ja fun òmìnira àwọn Júù,

19 3.19: Mk 2.1; 7.1. àti Judasi Iskariotu, ẹni ó fi í hàn níkẹyìn.

Jesu àti Beelsebulu

20 3.20: Mk 6.31. Nígbà náà ni Jesu wọ inú ilé kan, àwọn èrò tún kórajọ, bẹ́̀ Òun àti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ààyè láti jẹun. 21 3.21: Mk 3.31-35; Jh 10.20.Nígbà àwọn ẹbí rẹ̀ gbọ́ èyí, wọ́n láti un lọ ilé, nítorí wọn , "Orí rẹ̀ ti dàrú."

22 3.22-27: Mt 12.24-29; Lk 11.15-22. 3.22: Mt 9.34; 10.25. Àwọn olùkọ́ni òfin sọ̀kalẹ̀ láti Jerusalẹmu, wọ́n , "Ó ni Beelsebulu, olórí àwọn ̀èṣù, ni ó fi ń àwọn ̀èṣù jáde!"

23 Jesu wọ́n, ó fi òwe wọn sọ̀rọ̀: "Báwo ni Èṣù ṣe èṣù jáde? 24 ìjọba kan yapa ara rẹ̀, ìjọba náà yóò lulẹ̀. 25 Bákan náà, ilé kan yapa ara rẹ, ilé náà yóò le è dúró. 26 Èṣù dìde ara rẹ̀, ó yapa, òun yóò le è dúró ṣùgbọ́n òpin rẹ̀ yóò . 27 3.27: Isa 49.24-25.ẹni ó le wọ ilé ọkùnrin alágbára kan lọ, ó o ẹrù lọ, ṣe ó kọ́kọ́ de ọkùnrin alágbára náà okùn, nígbà náà ni yóò ẹrù ilé rẹ̀. 28 3.28-30: Mt 12.31-32; Lk 12.10.Lóòótọ́ mo fún yín, gbogbo ̀ṣẹ̀ ni a ó dáríjì àwọn ọmọ ènìyàn, àti gbogbo ̀rọ̀-òdì. 29 Ṣùgbọ́n ẹni ó sọ̀rọ̀-òdì ̀Mímọ́, yóò ìdáríjì títí ayé, ṣùgbọ́n ó nínú ewu ̀bi àìnípẹ̀kun."

30 Òun sọ eléyìí fún wọn, nítorí wọ́n sọ , "Nípa agbára ̀àìmọ́ ń ṣe àwọn iṣẹ́ ìyanu rẹ̀."

Ìyá àti àwọn Arákùnrin Jesu

31 3.31-35: Mt 12.46-50; Lk 8.19-21. Nígbà náà ni àwọn arákùnrin rẹ̀ àti ìyá , wọ́n dúró lóde, wọ́n ránṣẹ́ i, wọ́n ń é. 32 Àwọn ènìyàn wọ́n jókòó lọ́dọ̀ rẹ̀ fún un , "Ìyá àti àwọn arákùnrin rẹ lóde."

33 Ṣùgbọ́n ó wọn lóhùn , "Ta ni í ṣe ìyá mi tàbí àwọn arákùnrin mi?"

34 Ó gbogbo àwọn ó jókòó lọ́dọ̀ rẹ̀ yíká, ó , "Àwọn wọ̀nyí ni ìyá mi àti àwọn arákùnrin mi. 35 Nítorí ẹnikẹ́ni ó ń ṣe ìfẹ́ Ọlọ́run, òun ni arákùnrin mi àti arábìnrin mi àti ìyá mi."

Veja também