Pular para o conteúdo
Publicidade

Marcos 5

Ìwòsàn ọkùnrin ẹlẹ́mìí èṣù

1 5.1-20: Mt 8.28-34; Lk 8.26-39. Wọ́n lọ apá kejì adágún ̀ilẹ̀ àwọn ará Gadara. 2 Jesu ti ń ti inú ọkọ̀ ojú omi jáde. Ọkùnrin kan ó ̀àìmọ́ jáde ti ibojì pàdé rẹ̀. 3 Ọkùnrin yìí ń gbé nínú ibojì, ẹni ó é mọ́, kódà ̀wọ̀n le é. 4 Nítorí nígbà púpọ̀ ni wọ́n ti ń fi ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ é lọ́wọ́ àti ẹsẹ̀, ó ń a dànù kúrò ni ẹsẹ̀ rẹ̀. ẹnìkan ó agbára láti káwọ́ rẹ̀. 5 Tọ̀sán tòru láàrín àwọn ibojì àti àwọn òkè ni ó máa ń kígbe rara ó ń fi òkúta ya ara rẹ̀.

6 Nígbà ó Jesu látòkèrè, ó sáré lọ láti pàdé rẹ̀. Ó wólẹ̀ níwájú rẹ̀. 7 5.7: Ap 16.17; Hb 7.1; Mk 1.24.Ó kígbe ohùn rara , "ṣe tèmi tìrẹ, Jesu Ọmọ Ọlọ́run ̀gá-ògo? Mo fi Ọlọ́run bẹ̀ ́ ṣe mi lóró." 8 Nítorí Ó fún un , "Jáde kúrò lára ọkùnrin náà, ìwọ ̀àìmọ́!"

9 Jesu bi í léèrè , "ni orúkọ rẹ?"

̀àìmọ́ náà dáhùn , "Ligioni, nítorí àwa pọ̀." 10 Nígbà náà ni ̀àìmọ́ náà bẹ̀rẹ̀ í bẹ Jesu gidigidi, ó ṣe rán àwọn jáde kúrò agbègbè náà.

11 Agbo ẹlẹ́dẹ̀ ńlá kan ń jẹ lẹ́bàá òkè. 12 Àwọn ̀àìmọ́ náà bẹ Jesu , "Rán wa lọ sínú àwọn ẹlẹ́dẹ̀ wọ̀n-ọn-nì àwa le è wọ inú wọn lọ." 13 Jesu fún wọn láààyè, àwọn ̀àìmọ́ náà jáde kúrò lára ọkùnrin náà, wọ́n wọ inú àwọn ẹlẹ́dẹ̀ náà lọ. Agbo ẹlẹ́dẹ̀ náà ó ìwọ̀n ẹgbẹ̀rún méjì (2,000) túká lọ́gán, wọ́n sáré lọ gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ òkè rọ́ sínú Òkun, wọ́n ṣègbé.

14 Àwọn olùtọ́ẹran wọ̀nyí sálọ àwọn ìlú ńlá àti ìlú kéékèèké, wọ́n ń tan ìròyìn náà wọ́n ti ń sáré. Àwọn ènìyàn jáde láti fojú gán-án-ní ohun náà ó ṣẹlẹ̀. 15 Nígbà wọ́n péjọ sọ́dọ̀ Jesu, wọ́n ọkùnrin náà, ẹni ó ̀èṣù, ó jókòó níbẹ̀, ó wọ aṣọ ìyè rẹ bọ̀ sípò, ̀wọ́n. 16 Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ yìí ṣojú wọn ń ròyìn rẹ̀ fún àwọn ènìyàn ohun ó ṣẹlẹ̀ ọkùnrin ẹlẹ́mìí àìmọ́, wọ́n si sọ nípa agbo ẹlẹ́dẹ̀ náà pẹ̀. 17 Nígbà náà, àwọn èrò bẹ̀rẹ̀ bẹ Jesu ó fi agbègbè àwọn sílẹ̀.

18 Jesu ti ń wọ inú ọkọ̀ ojú omi lọ, ọkùnrin náà ó ti ̀àìmọ́ tẹ́lẹ̀ bẹ̀ ́ òun a lọ. 19 Jesu gbà fún un, ṣùgbọ́n ó fún un , "Lọ ilé ̀dọ̀ àwọn ẹbí rẹ, o sọ fún wọn Ọlọ́run ti ṣe ohun ńlá fún , àti ó ti ṣàánú fún ." 20 5.20: Mk 7.31.Nítorí náà, ọkùnrin yìí padà lọ, ó bẹ̀rẹ̀ ròyìn Dekapoli nípa ohun ńlá Jesu ṣe fún un. Ẹnu ya gbogbo ènìyàn.

Òkú ọmọbìnrin kan àti obìnrin aláìsàn

21 5.21-43: Mt 9.18-26; Lk 8.40-56. Nígbà Jesu ti inú ọkọ̀ rékọjá apá kejì Òkun, ̀pọ̀ ìjọ ènìyàn péjọ i etí Òkun. 22 5.22: Lk 13.14; Ap 13.15; 18.8,17.̀kan nínú àwọn olórí Sinagọgu à ń ni Jairu sọ́dọ̀ Jesu, nígbà ó i, ó wólẹ̀ níwájú rẹ̀. 23 5.23: Mk 6.5; 7.32; 8.23; Ap 9.17; 28.8.Ó bẹ̀ ́ gidigidi , "Ọmọbìnrin mi lójú ikú, mo bẹ̀ ́, fi ọwọ́ rẹ e, ara rẹ̀ , ó ." 24 Jesu ń a lọ.

̀pọ̀ ìjọ ènìyàn ń tọ̀ ́ lẹ́yìn. 25 Obìnrin kan láàrín ̀pọ̀ ènìyàn náà, ó ti ìsun ̀jẹ̀ fún odidi ọdún méjìlá. 26 Ẹni ojú rẹ̀ ti ̀pọ̀lọpọ̀ ìpọ́njú lọ́dọ̀ ̀pọ̀ àwọn oníṣègùn, ó ti gbogbo ohun ó , síbẹ̀ kàkà ó san, ó ń burú i. 27 Nígbà ó gbúròó iṣẹ́ ìyanu Jesu ṣe, ìdí nìyìí ó fi sẹ́yìn rẹ̀, láàrín ̀pọ̀ ènìyàn, ó fọwọ́ kan aṣọ rẹ̀. 28 Nítorí ti ó ọkàn rẹ̀ , "mo à fi ọwọ́ kan aṣọ rẹ̀, ara mi yóò ." 29 Ìsun ̀jẹ̀ rẹ̀ gbẹ lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀, òun mọ̀ lára rẹ̀ , a òun láradá kúrò nínú ààrùn náà.

30 5.30: Lk 5.17. Lọ́gán, Jesu mọ̀ nínú ara rẹ̀ agbára jáde lára òun. Ó yípadà láàrín ̀pọ̀ ènìyàn, ó béèrè, "Ta ni ó fi ọwọ́ kan aṣọ mi?"

31 Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ fún un , "Ìwọ ̀pọ̀ ènìyàn ó rọ̀gbà , ìwọ tún ń béèrè ẹni ó fi ọwọ́ kàn ́?"

32 Síbẹ̀, Jesu bẹ̀rẹ̀ yíká láti ẹni náà, ó fi ọwọ́ kan òun. 33 Nígbà náà, obìnrin náà kún fún ìbẹ̀àti ìwárìrì nítorí ó ti mọ ohun ó ṣẹlẹ̀ lára òun. Ó kúnlẹ̀ níwájú rẹ̀, ó sọ gbogbo òtítọ́ fún un. 34 5.34: Lk 7.50; Mk 10.52.Jesu fún un , "Ọmọbìnrin, ìgbàgbọ́ rẹ láradá. Máa lọ àlàáfíà, ìwọ ti sàn nínú ààrùn rẹ."

35 Jesu ti ń ba obìnrin náà sọ̀rọ̀, àwọn ìránṣẹ́ láti ilé Jairu olórí Sinagọgu , wọ́n fún un , ọmọbìnrin rẹ ti , àti wọn ṣe yọ Jesu lẹ́nu láti , nítorí ó ti pẹ́ .

36 Ṣùgbọ́n bi Jesu ti gbọ́ ̀rọ̀ náà, ó fún Jairu , "bẹ̀, à gbàgbọ́ nìkan."

37 5.37: Mk 9.2; 13.3. Nígbà náà, Jesu ̀pọ̀ ènìyàn náà dúró. jẹ́ ẹnikẹ́ni tẹ̀òun lẹ́yìn lọ ilé Jairu, ṣe Peteru, Jakọbu àti Johanu arákùnrin Jakọbu. 38 Nígbà wọ́n ibẹ̀, Jesu i gbogbo nǹkan ti dàrú. Ilé kún fún àwọn ń sọkún, àti àwọn ń pohùnréré ẹkún. 39 Ó wọ inú ilé lọ, o àwọn ènìyàn sọ̀rọ̀, ó béèrè , "Èéṣe ̀yin fi ń sọkún ń pohùnréré ẹkún? Ọmọbìnrin náà , ó sùn lásán ni." 40 Wọ́n fi í rẹ́rìn-ín.

Ṣùgbọ́n ó sọ fún gbogbo wọn láti bọ́ síta, ó baba àti ìyá ọmọ náà, àti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ mẹ́ta. Ó wọ inú yàrá ọmọbìnrin náà gbé dùbúlẹ̀ . 41 5.41: Lk 7.14; Ap 9.40.Ó gbá a ọwọ́ , ó , "Talita kuumi" (ó túmọ̀ "Ọmọdébìnrin, dìde dúró!"). 42 Lẹ́sẹ̀kan náà, ọmọbìnrin náà dìde. Ó ń rìn, ̀wọ́n, ẹnu ya àwọn òbí rẹ̀ gidigidi. 43 5.43: Mk 1.43-44; 7.36.Jesu kìlọ̀ fún wọn gidigidi wọn ṣe sọ ohun ó ti ṣẹlẹ̀. Ó fún wọn wọn fún ọmọbìnrin náà oúnjẹ.

Veja também