Publicidade

Marcos 5

Ìwòsàn ọkùnrin ẹlẹ́mìí èṣù

1 Wọ́n lọ apá kejì adágún ̀ilẹ̀ àwọn ará Gadara. 2 Jesu ti ń ti inú ọkọ̀ ojú omi jáde. Ọkùnrin kan ó ̀àìmọ́ jáde ti ibojì pàdé rẹ̀. 3 Ọkùnrin yìí ń gbé nínú ibojì, ẹni ó é mọ́, kódà ̀wọ̀n le é. 4 Nítorí nígbà púpọ̀ ni wọ́n ti ń fi ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ é lọ́wọ́ àti ẹsẹ̀, ó ń a dànù kúrò ni ẹsẹ̀ rẹ̀. ẹnìkan ó agbára láti káwọ́ rẹ̀. 5 Tọ̀sán tòru láàrín àwọn ibojì àti àwọn òkè ni ó máa ń kígbe rara ó ń fi òkúta ya ara rẹ̀.

6 Nígbà ó Jesu látòkèrè, ó sáré lọ láti pàdé rẹ̀. Ó wólẹ̀ níwájú rẹ̀. 7 Ó kígbe ohùn rara , "ṣe tèmi tìrẹ, Jesu Ọmọ Ọlọ́run ̀gá-ògo? Mo fi Ọlọ́run bẹ̀ ́ ṣe mi lóró." 8 Nítorí Ó fún un , "Jáde kúrò lára ọkùnrin náà, ìwọ ̀àìmọ́!"

9 Jesu bi í léèrè , "ni orúkọ rẹ?"

̀àìmọ́ náà dáhùn , "Ligioni, nítorí àwa pọ̀." 10 Nígbà náà ni ̀àìmọ́ náà bẹ̀rẹ̀ í bẹ Jesu gidigidi, ó ṣe rán àwọn jáde kúrò agbègbè náà.

11 Agbo ẹlẹ́dẹ̀ ńlá kan ń jẹ lẹ́bàá òkè. 12 Àwọn ̀àìmọ́ náà bẹ Jesu , "Rán wa lọ sínú àwọn ẹlẹ́dẹ̀ wọ̀n-ọn-nì àwa le è wọ inú wọn lọ." 13 Jesu fún wọn láààyè, àwọn ̀àìmọ́ náà jáde kúrò lára ọkùnrin náà, wọ́n wọ inú àwọn ẹlẹ́dẹ̀ náà lọ. Agbo ẹlẹ́dẹ̀ náà ó ìwọ̀n ẹgbẹ̀rún méjì (2,000) túká lọ́gán, wọ́n sáré lọ gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ òkè rọ́ sínú Òkun, wọ́n ṣègbé.

14 Àwọn olùtọ́ẹran wọ̀nyí sálọ àwọn ìlú ńlá àti ìlú kéékèèké, wọ́n ń tan ìròyìn náà wọ́n ti ń sáré. Àwọn ènìyàn jáde láti fojú gán-án-ní ohun náà ó ṣẹlẹ̀. 15 Nígbà wọ́n péjọ sọ́dọ̀ Jesu, wọ́n ọkùnrin náà, ẹni ó ̀èṣù, ó jókòó níbẹ̀, ó wọ aṣọ ìyè rẹ bọ̀ sípò, ̀wọ́n. 16 Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ yìí ṣojú wọn ń ròyìn rẹ̀ fún àwọn ènìyàn ohun ó ṣẹlẹ̀ ọkùnrin ẹlẹ́mìí àìmọ́, wọ́n si sọ nípa agbo ẹlẹ́dẹ̀ náà pẹ̀. 17 Nígbà náà, àwọn èrò bẹ̀rẹ̀ bẹ Jesu ó fi agbègbè àwọn sílẹ̀.

18 Jesu ti ń wọ inú ọkọ̀ ojú omi lọ, ọkùnrin náà ó ti ̀àìmọ́ tẹ́lẹ̀ bẹ̀ ́ òun a lọ. 19 Jesu gbà fún un, ṣùgbọ́n ó fún un , "Lọ ilé ̀dọ̀ àwọn ẹbí rẹ, o sọ fún wọn Ọlọ́run ti ṣe ohun ńlá fún , àti ó ti ṣàánú fún ." 20 Nítorí náà, ọkùnrin yìí padà lọ, ó bẹ̀rẹ̀ ròyìn Dekapoli nípa ohun ńlá Jesu ṣe fún un. Ẹnu ya gbogbo ènìyàn.

Òkú ọmọbìnrin kan àti obìnrin aláìsàn

21 Nígbà Jesu ti inú ọkọ̀ rékọjá apá kejì Òkun, ̀pọ̀ ìjọ ènìyàn péjọ i etí Òkun. 22 ̀kan nínú àwọn olórí Sinagọgu à ń ni Jairu sọ́dọ̀ Jesu, nígbà ó i, ó wólẹ̀ níwájú rẹ̀. 23 Ó bẹ̀ ́ gidigidi , "Ọmọbìnrin mi lójú ikú, mo bẹ̀ ́, fi ọwọ́ rẹ e, ara rẹ̀ , ó ." 24 Jesu ń a lọ.

̀pọ̀ ìjọ ènìyàn ń tọ̀ ́ lẹ́yìn. 25 Obìnrin kan láàrín ̀pọ̀ ènìyàn náà, ó ti ìsun ̀jẹ̀ fún odidi ọdún méjìlá. 26 Ẹni ojú rẹ̀ ti ̀pọ̀lọpọ̀ ìpọ́njú lọ́dọ̀ ̀pọ̀ àwọn oníṣègùn, ó ti gbogbo ohun ó , síbẹ̀ kàkà ó san, ó ń burú i. 27 Nígbà ó gbúròó iṣẹ́ ìyanu Jesu ṣe, ìdí nìyìí ó fi sẹ́yìn rẹ̀, láàrín ̀pọ̀ ènìyàn, ó fọwọ́ kan aṣọ rẹ̀. 28 Nítorí ti ó ọkàn rẹ̀ , "mo à fi ọwọ́ kan aṣọ rẹ̀, ara mi yóò ." 29 Ìsun ̀jẹ̀ rẹ̀ gbẹ lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀, òun mọ̀ lára rẹ̀ , a òun láradá kúrò nínú ààrùn náà.

30 Lọ́gán, Jesu mọ̀ nínú ara rẹ̀ agbára jáde lára òun. Ó yípadà láàrín ̀pọ̀ ènìyàn, ó béèrè, "Ta ni ó fi ọwọ́ kan aṣọ mi?"

31 Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ fún un , "Ìwọ ̀pọ̀ ènìyàn ó rọ̀gbà , ìwọ tún ń béèrè ẹni ó fi ọwọ́ kàn ́?"

32 Síbẹ̀, Jesu bẹ̀rẹ̀ yíká láti ẹni náà, ó fi ọwọ́ kan òun. 33 Nígbà náà, obìnrin náà kún fún ìbẹ̀àti ìwárìrì nítorí ó ti mọ ohun ó ṣẹlẹ̀ lára òun. Ó kúnlẹ̀ níwájú rẹ̀, ó sọ gbogbo òtítọ́ fún un. 34 Jesu fún un , "Ọmọbìnrin, ìgbàgbọ́ rẹ láradá. Máa lọ àlàáfíà, ìwọ ti sàn nínú ààrùn rẹ."

35 Jesu ti ń ba obìnrin náà sọ̀rọ̀, àwọn ìránṣẹ́ láti ilé Jairu olórí Sinagọgu , wọ́n fún un , ọmọbìnrin rẹ ti , àti wọn ṣe yọ Jesu lẹ́nu láti , nítorí ó ti pẹ́ .

36 Ṣùgbọ́n bi Jesu ti gbọ́ ̀rọ̀ náà, ó fún Jairu , "bẹ̀, à gbàgbọ́ nìkan."

37 Nígbà náà, Jesu ̀pọ̀ ènìyàn náà dúró. jẹ́ ẹnikẹ́ni tẹ̀òun lẹ́yìn lọ ilé Jairu, ṣe Peteru, Jakọbu àti Johanu arákùnrin Jakọbu. 38 Nígbà wọ́n ibẹ̀, Jesu i gbogbo nǹkan ti dàrú. Ilé kún fún àwọn ń sọkún, àti àwọn ń pohùnréré ẹkún. 39 Ó wọ inú ilé lọ, o àwọn ènìyàn sọ̀rọ̀, ó béèrè , "Èéṣe ̀yin fi ń sọkún ń pohùnréré ẹkún? Ọmọbìnrin náà , ó sùn lásán ni." 40 Wọ́n fi í rẹ́rìn-ín.

Ṣùgbọ́n ó sọ fún gbogbo wọn láti bọ́ síta, ó baba àti ìyá ọmọ náà, àti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ mẹ́ta. Ó wọ inú yàrá ọmọbìnrin náà gbé dùbúlẹ̀ . 41 Ó gbá a ọwọ́ , ó , "Talita kuumi" (ó túmọ̀ "Ọmọdébìnrin, dìde dúró!"). 42 Lẹ́sẹ̀kan náà, ọmọbìnrin náà dìde. Ó ń rìn, ̀wọ́n, ẹnu ya àwọn òbí rẹ̀ gidigidi. 43 Jesu kìlọ̀ fún wọn gidigidi wọn ṣe sọ ohun ó ti ṣẹlẹ̀. Ó fún wọn wọn fún ọmọbìnrin náà oúnjẹ.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-