Pular para o conteúdo
Publicidade

Marku 6

22 Nígbà náà, ni ọmọbìnrin Herodia wọlé láti . Inú Herodu àti àwọn àlejò rẹ̀ dùn bẹ́̀.

Ọba sọ fún ọmọbìnrin náà , "Béèrè ohunkóhun ìwọ fẹ́ lọ́wọ́ mi, èmi ó fi fún ." 23 6.23: Es 5.3,6.Ó búra fún un , "Ohunkóhun ìwọ fẹ́, ìbá à ṣe ìdajì ìjọba mi ni, èmi yóò fi fún ."

24 Ó jáde lọ sọ fún ìyá rẹ̀ , "ń béèrè?"

Ó dáhùn , "Orí Johanu Onítẹ̀bọmi."

25 Ọmọbìnrin yìí sáré padà sọ́dọ̀ Herodu ọba. Ó fún un , "Mo ń fẹ́ orí Johanu Onítẹ̀bọmi nísinsin yìí nínú àwopọ̀kọ́."

26 Inú ọba bàjẹ́ gidigidi, ṣùgbọ́n nítorí àwọn ìbúra rẹ, àti nítorí àwọn ó a jókòó pọ̀, fẹ́ kọ̀ fún un. 27 Nítorí èyí, ọba rán ̀ṣọ́ kan, ó fi àṣẹ fún un , ó gbé orí Johanu . Ọkùnrin náà lọ, ó bẹ́ Johanu lórí nínú túbú. 28 Ó gbé orí Johanu wa nínú àwopọ̀kọ́. Ó gbé e fún ọmọbìnrin náà. Òun gbé e tọ ìyá rẹ̀ lọ.

Veja também