Publicidade

Marcos 7

Mímọ́ àti àìmọ́

1 Àwọn Farisi péjọ ̀dọ̀ rẹ̀, àti àwọn kan nínú àwọn akọ̀, ó láti Jerusalẹmu, 2 wọ́n ṣe àkíyèsí díẹ̀ nínú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Jesu ń fi ọwọ́ àìmọ́ jẹun, èyí yìí ni wẹ ọwọ́. 3 (Àwọn Farisi, àti gbogbo àwọn Júù, wọ́n wẹ ọwọ́ wọn gidigidi, wọn í jẹun nítorí wọ́n ti pa òfin àtọwọ́dọ́wọ́ àwọn àgbà mọ́. 4 Nígbà wọ́n ti ọjà sílé, wọn gbọdọ̀ fi ọwọ́ kan oúnjẹ àfi wọ́n bu omi wẹ ara wọn. Èyí jẹ́ ̀kan nínú ogunlọ́gọ̀ àpẹẹrẹ òfin àti ìlànà wọ́n ti fún ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún sẹ́yìn, i fífọ kọ́̀, àwọn ìkòkò, àti kẹ́.)

5 Nítorí èyí àwọn Farisi àti àwọn olùkọ́ òfin béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ , "Èéṣe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ tẹ̀àwọn òfin àtọwọ́dọ́wọ́ àwọn àgbà nítorí wọ́n fi ọwọ́ àìmọ́ jẹun?"

6 Jesu wọn lóhùn , "Ẹyin àgàbàgebè yìí, òtítọ́ ni wòlíì Isaiah ń sọtẹ́lẹ̀ nípa ̀yin àgàbàgebè, a ti kọ ́ :

" Àwọn ènìyàn wọ̀nyí fi ẹnu wọn bu ọlá fún mi

ṣùgbọ́n ọkàn wọn jìnà mi.

7 Ìsìn wọn jẹ́ lásán,

ìkọ́ni wọ́n jẹ́ kìkìdá òfin àwọn ènìyàn fi ń kọ́ni.

8 Nítorí ̀yin fi òfin Ọlọ́run apá kan, ̀yin ń tẹ̀àṣà àwọn ènìyàn."

9 Ó si fún wọn: "̀yin à mọ̀ ti ń gbé òfin Ọlọ́run sẹ́yìn òfin tiyín ṣẹ. 10 Mose fún un yín òfin yìí láti ̀dọ̀ Ọlọ́run , Bọ̀wọ̀ fún baba òun ìyá rẹ.Ó tún sọ , Ẹnikẹ́ni ó sọ̀rọ̀ aburú baba tàbí ìyá rẹ̀ láti ni. 11 Ṣùgbọ́n ̀yin sọ ó dára bákan náà fún ọkùnrin kan tilẹ̀ pèsè fún àìní àwọn òbí rẹ̀, ṣùgbọ́n o sọ fún wọn , ṣe bínú baba tàbí ìyá mi, n ràn yín lọ́wọ́ nísinsin yìí,nítorí mo ti fi ̀bùn ǹ fi fún un yín fún Ọlọ́run. 12 Bẹ́̀ ni ̀yin si jẹ́ ó ṣe ohunkóhun fún baba tàbí ìyá rẹ̀ mọ́. 13 ̀yin ń fi òfin àtọwọ́dọ́wọ́ tiyín fi lélẹ̀, sọ ̀rọ̀ Ọlọ́run di asán àti ̀pọ̀ irú nǹkan bẹ́̀ ni ̀yin ń ṣe."

14 Lẹ́yìn náà, Jesu pe ̀pọ̀ ènìyàn láti gbọ́ ̀rọ̀ rẹ̀. Ó fún wọn , "Gbogbo yín tẹ́sílẹ̀ jẹ́ èyí ó e yín. 15 ohunkóhun láti òde ènìyàn, ó wọ inú rẹ̀ lọ, ó sọ ́ di aláìmọ́, ṣùgbọ́n àwọn nǹkan ó ti inú rẹ jáde, àwọn wọ̀nyí ń sọ ènìyàn di aláìmọ́."

17 Nígbà Jesu wọ inú ilé kan lọ, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn tẹ̀é, wọ́n béèrè ìtumọ̀ àwọn òwe ó pa. 18 Jesu béèrè , "Àbí èyí ó yín nínú ̀rọ̀ náà? ̀yin i ohunkóhun ó wọ inú ènìyàn láti òde sọ ènìyàn di aláìmọ́? 19 Nítorí lọ sínú ọkàn rẹ̀, ṣùgbọ́n sínú ara, a á jáde, a gbá gbogbo oúnjẹ dànù." (Nípa sísọ èyí, Jesu fihàn gbogbo oúnjẹ jẹ́ "mímọ́.")

20 Nígbà náà, ó fi kún un , "Èyí ti ó ti ọkàn ènìyàn jáde ni ń sọ ni di aláìmọ́. 21 Nítorí láti inú ọkàn ènìyàn ni àwọn èrò búburú wọ̀nyí ti ń jáde : àgbèrè, olè, ìpànìyàn, panṣágà, 22 ̀kánjúwà, odì yíyàn, ìtànjẹ, ìmọ-tara-ẹni, ìlara, ̀rọ̀ ̀yìn, ìgbéraga, òmùgọ̀. 23 Gbogbo àwọn nǹkan búburú wọ̀nyí ń inú , àwọn ń sọ yín di aláìmọ́."

Ìgbàgbọ́ obìnrin ará Kenaani

24 Nígbà náà ni Jesu kúrò Galili, ó lọ agbègbè Tire àti Sidoni, ó gbìyànjú láti nìkan pẹ̀àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ fún àkókò díẹ̀, ṣùgbọ́n eléyìí ṣe é ṣe, nítorí pẹ́ púpọ̀ ó wọ ìlú nígbà ìròyìn dídé rẹ̀ tàn káàkiri. 25 Láìpẹ́, obìnrin kan ọmọbìnrin rẹ̀ ̀àìmọ́ tọ̀ ́ , ó ti gbọ́ nípa Jesu, ó , ó wólẹ̀ lẹ́sẹ̀ Jesu. 26 Giriki obìnrin náà, Siro-Fonisia orílẹ̀-èdè rẹ̀. Ó bẹ Jesu ó òun ̀èṣù náà jáde lára ọmọbìnrin òun.

27 Jesu sọ fún obìnrin yìí , "àkọ́kọ́, ó yẹ a fi oúnjẹ tẹ́ àwọn ọmọ lọ́rùn . Nítorí tọ́ a oúnjẹ àwọn ọmọ fún àwọn ajá."

28 Obìnrin náà dáhùn , "Òótọ́ ni ̀rọ̀ yín Olúwa, ṣùgbọ́n àwọn ọmọ ajá pàápàá a máa àǹfààní láti jẹ èérún oúnjẹ ó bọ́ sílẹ̀ láti orí tábìlì."

29 "Ó fún un , nítorí ̀rọ̀ yìí, máa lọ, ̀àìmọ́ náà ti jáde kúrò lára ọmọbìnrin rẹ."

30 Nígbà ó padà ilé, ó ọmọbìnrin rẹ̀ ìdùbúlẹ̀ jẹ́jẹ́ lórí ibùsùn, ̀àìmọ́ náà ti fi í sílẹ̀.

Ìwòsàn ọkùnrin odi àti afọ́

31 Nígbà náà ni Jesu fi agbègbè Tire àti Sidoni sílẹ̀, ó si Òkun Galili láàrín agbègbè Dekapoli. 32 Níbẹ̀ ọkùnrin kan sọ̀rọ̀ ̀dọ̀ Jesu, àwọn ènìyàn bẹ Jesu ó gbé ọwọ́ rẹ̀ e.

33 Jesu ọkùnrin náà kúrò láàrín ̀pọ̀ ènìyàn. Ó fi àwọn ìka rẹ̀ etí ọkùnrin náà, ó tu itọ́ ṣọ́wọ́. Ó fi kan ahọ́n rẹ̀. 34 Nígbà náà ni Jesu wòkè ̀run, ó kanlẹ̀, ó pàṣẹ , "Efata!" (èyí ni, "Ìwọ ṣí!"). 35 Lójúkan náà, etí rẹ̀ ṣí, okùn ahọ́n rẹ̀ , ó ń sọ̀rọ̀ ketekete.

36 Jesu pàṣẹ fún ̀pọ̀ ènìyàn níbẹ̀ wọn ṣe tan ìròyìn náà . Ṣùgbọ́n ó ti ń pa wọ́n lẹ́nu mọ́ , náà ni wọ́n ń tan ìròyìn náà káàkiri . 37 Àwọn ènìyàn kún fún ìyanu, wọ́n , "Ó ṣe ohun gbogbo dáradára, Ó adití gbọ́rọ̀, odi sọ̀rọ̀."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-