Pular para o conteúdo
Publicidade

Marku 7

9 Ó si fún wọn: "̀yin à mọ̀ ti ń gbé òfin Ọlọ́run sẹ́yìn òfin tiyín ṣẹ. 10 7.10: Ek 20.12; De 5.16; Ek 21.17; Le 20.9.Mose fún un yín òfin yìí láti ̀dọ̀ Ọlọ́run , Bọ̀wọ̀ fún baba òun ìyá rẹ.Ó tún sọ , Ẹnikẹ́ni ó sọ̀rọ̀ aburú baba tàbí ìyá rẹ̀ láti ni. 11 Ṣùgbọ́n ̀yin sọ ó dára bákan náà fún ọkùnrin kan tilẹ̀ pèsè fún àìní àwọn òbí rẹ̀, ṣùgbọ́n o sọ fún wọn , ṣe bínú baba tàbí ìyá mi, n ràn yín lọ́wọ́ nísinsin yìí,nítorí mo ti fi ̀bùn ǹ fi fún un yín fún Ọlọ́run. 12 Bẹ́̀ ni ̀yin si jẹ́ ó ṣe ohunkóhun fún baba tàbí ìyá rẹ̀ mọ́. 13 ̀yin ń fi òfin àtọwọ́dọ́wọ́ tiyín fi lélẹ̀, sọ ̀rọ̀ Ọlọ́run di asán àti ̀pọ̀ irú nǹkan bẹ́̀ ni ̀yin ń ṣe."

Veja também