Publicidade

Marcos 9

1 9.1: Mk 13.30; Mt 10.23; Lk 22.18. Ó fún wọn , "Lóòótọ́ ni mo fún un yín àwọn mìíràn wa nínú àwọn dúró níhìn-ín yìí, yóò tọ́ ikú , títí yóò fi ìjọba Ọlọ́run yóò fi pẹ̀agbára."

Ìparadà

2 9.2-8: Mt 17.1-8; Lk 9.28-36. 9.2: Mk 5.37; 13.3. Lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́Jesu sọ̀rọ̀ yìí, Jesu Peteru, Jakọbu àti Johanu lọ orí òkè gíga apá kan. ẹlòmíràn pẹ̀wọn, ara rẹ̀ yípadà níwájú wọn. 3 9.3: Mt 28.3.Aṣọ rẹ̀ di dídán, ó funfun gbòò, alágbàfọ̀ kan ayé sọ di funfun bẹ́̀. 4 Nígbà náà ni Elijah àti Mose farahàn fún wọn, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sọ̀rọ̀ pẹ̀Jesu.

5 Peteru fún Jesu , "Rabbi, ó dára fún wa láti máa gbé níhìn-ín, si jẹ́ a pa àgọ́ mẹ́ta, ̀kan fun , ̀kan fún Mose, àti ̀kan fún Elijah." 6 Nítorí òun mọ ohun òun ìbá sọ, nítorí ̀wọ́n gidigidi.

7 9.7: 2Pt 1.17-18; Mt 3.17; Jh 12.28-29. Ìkùùkuu kan wọ́n, ohùn kan ti inú ìkùùkuu náà , "Èyí ni àyànfẹ́ ọmọ mi. máa gbọ́ ti rẹ̀!"

8 Lójijì, wọ́n wo àyíká wọn, wọn ẹnìkankan mọ́, ṣe Jesu nìkan ṣoṣo ni ó pẹ̀wọn.

9 9.9-13: Mt 17.9-13; Lk 9.36. 9.9: Mk 8.30; 5.43; 7.36. wọ́n ti ń sọ̀kalẹ̀ láti orí òkè, Jesu kìlọ̀ fún wọn wọ́n ṣe sọ ohun wọ́n ti fún ẹnikẹ́ni títí Ọmọ Ènìyàn yóò fi jíǹde kúrò nínú òkú. 10 Nítorí náà, wọ́n pa nǹkan náà mọ́ ọkàn wọn. Ṣùgbọ́n wọ́n ń béèrè lọ́wọ́ ara wọn ohun àjíǹde kúrò nínú òkú túmọ̀ .

11 9.11: Mt 11.14. Nísinsin yìí, wọ́n bẹ̀rẹ̀ í béèrè lọ́wọ́ rẹ̀, èéṣe àwọn olùkọ́ òfin ń sọ , "Elijah yóò kọ́kọ́ ."

12 9.12: Mk 8.31; 9.31; 10.33. Ó dáhùn ó fún wọn , "Lóòótọ́ ni Elijah yóò kọ́kọ́ yóò nǹkan gbogbo padà bọ̀ sípò. Àní gẹ́gẹ́ a ti kọ̀rẹ nípa ti Ọmọ Ènìyàn le ṣàìmá jìyà ohun púpọ̀ àti a ó kọ̀ ́ sílẹ̀. 13 Ṣùgbọ́n mo fún yín , Elijah ti wa , wọ́n ti ṣe ohunkóhun ó wọ́n i, gẹ́gẹ́ a ti kọ̀nípa rẹ̀."

Ìwòsàn ọmọkùnrin ẹlẹ́mìí èṣù

14 9.14-27: Mt 17.14-18; Lk 9.37-43. Nígbà wọ́n sọ̀kalẹ̀ pátápátá ẹsẹ̀ òkè náà, wọ́n ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn wọ́n àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mẹ́sàn-án ìyókù . Àwọn olùkọ́ òfin díẹ̀ ń wọn jiyàn. 15 Jesu ti ń súnmọ́ ̀pọ̀ ènìyàn wọ̀nyí ni wọ́n ti bẹ̀rẹ̀ í ó pẹ̀ìbẹ̀, nígbà náà ni wọ́n sáré lọ i.

16 Jesu béèrè lọ́wọ́ wọn , "fa àríyànjiyàn?"

17 Ọkùnrin kan láàrín ̀pọ̀ ènìyàn dáhùn , "Olùkọ́, èmi ni mo ọmọ yìí fún láti ó sàn. sọ̀rọ̀ rárá, nítorí ó ̀àìmọ́. 18 Àti , nígbàkígbà ó un, á gbé e ṣánlẹ̀, a máa itọ́ lẹ́nu, a máa lọ́ eyín rẹ̀. Òun pàápàá a le gbagidi. Mo bẹ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ wọn ̀àìmọ́ náà jáde, ṣùgbọ́n wọ́n ṣe é."

19 Ó wọn lóhùn, ó , "̀yin ìran aláìgbàgbọ́ yìí, èmi yóò ti a yín gbé pẹ́ ? Èmi yóò ti sùúrù fún un yín pẹ́ ? ọmọ náà sọ́dọ̀ mi."

20 Wọ́n un sọ́dọ̀ rẹ̀: nígbà ó i, lójúkan náà ̀náà án tàntàn ó ṣubú lu ilẹ̀, ó ń fi ara yílẹ̀, ó ń yọ ìfófó lẹ́nu.

21 Jesu béèrè lọ́wọ́ baba ọmọ náà , "Ó ìgbà wo ọmọ rẹ̀ ti nínú irú ipò báyìí?"

Baba ọmọ náà dáhùn , "Láti kékeré ni." 22 Nígbàkígbà ni ó máa ń gbé e sínú iná àti sínú omi, láti pa á run, ṣùgbọ́n ìwọ ṣe ohunkóhun, ṣàánú fún wa, o ràn lọ́wọ́.

23 9.23: Mt 17.20; Lk 17.6; Mk 11.22-24. "Jesu fún un , ìwọ le gbàgbọ́: ohun gbogbo ni ó ṣe é ṣe fún ẹni ó gbàgbọ́.’ "

24 Lójúkan náà baba ọmọ náà kígbe ohùn rara, ó , "Olúwa, mo gbàgbọ́, ran àìgbàgbọ́ mi lọ́wọ́."

25 Nígbà Jesu i ̀pọ̀ ènìyàn ń péjọ sọ́dọ̀ wọn, ó ̀àìmọ́ náà , "Ìwọ ̀àìmọ́, adití àti odi, mo pàṣẹ fún , ó jáde kúrò lára ọmọ yìí, ó ṣe padà ibẹ̀ mọ́."

26 Òun kígbe ńlá, ó án tàntàn, ó jáde kúrò lára rẹ̀, ọmọ náà dàbí ẹni ó bẹ́̀ ̀pọ̀ ènìyàn , "è, ọmọ náà ti ." 27 Ṣùgbọ́n Jesu á lọ́wọ́, ó ràn án lọ́wọ́ láti dúró lórí ẹsẹ̀ rẹ̀. Ó dìde dúró.

28 Nígbà ó wọ ilé, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ bi í léèrè níkọ̀kọ̀ , "Èéṣe àwa fi e jáde?"

29 Ó fún wọn , "Irú èyí le ti ipa ohun kan jáde, ṣe nípa àdúrà."9.29 Àwọn àkọsílẹ̀ kan sọ pé, nípa ààwẹ̀ àti àdúrà

30 9.30-32: Mt 17.22-23; Lk 9.43-45. Wọ́n kúrò níbẹ̀, wọ́n gba Galili kọjá. Níbẹ̀ ni Jesu ti gbìyànjú láti yẹra ó à pẹ̀àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ó ráàyè kọ́ wọn lẹ́kọ̀́ i. 31 9.31: Mk 8.31; 10.33.Nítorí ó kọ́ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ó fun wọn pe, "A ó fi Ọmọ Ènìyàn àwọn ènìyàn lọ́wọ́, wọn ó pa á, lẹ́yìn ìgbà a pa á tan yóò jíǹde ọjọ́ kẹta." 32 9.32: Jh 12.16.Ṣùgbọ́n ̀rọ̀ náà wọn, ̀wọ́n láti béèrè lọ́wọ́ rẹ̀, ìtumọ̀ ohun ó sọ náà.

Ta ni o ga jùlọ?

33 9.33-37: Mt 18.1-5; Lk 9.46-48. Wọ́n Kapernaumu. Lẹ́yìn wọ́n sinmi tán nínú ilé wọ́n wọ̀, Jesu béèrè lọ́wọ́ wọn , "ni ohun ́ ń ara yín jiyàn lórí?" 34 9.34: Lk 22.24.Ṣùgbọ́n wọ́n dákẹ́; nítorí wọn ti ń ara wọn jiyàn , ta ni ẹni ó pọ̀?

35 9.35: Mk 10.43-44; Mt 20.26-27; 23.11; Lk 22.26. Ó jókòó, ó àwọn méjìlá náà, ó sọ fún wọn , "ẹnikẹ́ni fẹ́ ṣe ẹni ìṣáájú, òun ni yóò ṣe ẹni ìkẹyìn gbogbo wọn. Ó láti jẹ́ ìránṣẹ́ gbogbo ènìyàn."

36 9.36: Mk 10.16. Ó ọmọ kékeré kan, ó fi sáàárín wọn, nígbà ó gbé e apá rẹ̀, ó fún wọn , 37 9.37: Mt 10.40; Lk 10.16; Jh 12.44; 13.20."Ẹnikẹ́ni ó tẹ́wọ́gbà ọmọ kékeré èyí orúkọ mi, òun gbà . Ẹnikẹ́ni ó gbà mi, ó gba Baba mi, ó rán mi."

38 9.38-40: Lk 9.49-50; 11.23; Mt 12.30; Nu 11.27-29. ̀kan nínú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, Johanu sọ fún un ọjọ́ kan , "Olùkọ́, àwa ọkùnrin kan, ń fi orúkọ rẹ̀ àwọn ̀àìmọ́ jáde, ṣùgbọ́n a sọ fún un gbọdọ̀ ṣe bẹ́̀ mọ́, nítorí í ṣe ̀kan nínú wa."

39 Jesu sọ fún un , "ṣe irú ènìyàn bẹ́̀ dúró, nítorí ẹnìkan ti ó fi orúkọ mi ṣe iṣẹ́ ìyanu yóò tún máa sọ ohun búburú nípa mi. 40 Nítorí ẹni kọ ojú ìjà wa, ó ìhà tiwa. 41 9.41: Mt 10.42.Lóòótọ́ ni mo sọ fún ún yín ẹnikẹ́ni fún un yín ife omi kan nítorí jẹ́ ti Kristi, dájúdájú ẹni náà yóò sọ èrè rẹ̀ ó ti ó .

Okùnfà ̀ṣẹ̀

42 9.42-48: Mt 18.6-9; 5.29-30; Lk 17.1-2. "Ṣùgbọ́n ti ẹnikẹ́ni ̀kan nínú àwọn ọmọ kékeré wọ̀nyí ó gbà gbọ́ ṣìnà nínú ìgbàgbọ́ rẹ́, ó sàn fún un a so òkúta ńlá mọ́ ọn ni ̀run, a sọ ́ sínú òkun. 43 ọwọ́ rẹ kọsẹ̀, e sọnù, ó sàn fún o ṣe akéwọ́ lọ ibi ìyè, ju o ọwọ́ méjèèjì, o lọ ̀run àpáàdì, sínú iná àjóòkú.9.43 Àwọn àkọsílẹ̀ àtijọ́ ìwé Marku kan se àfikún ọ̀rọ̀ yìí àjóòkú. 44Níbi ti ‘kòkòrò wọn kì í kú, tí iná kì í sì í kú.’ 45 ẹsẹ̀ rẹ kọsẹ̀, é sọnù, ó sàn ó di akesẹ̀, o gbé títí ayé àìnípẹ̀kun ju o ẹsẹ̀ méjì ó gbé lọ ̀run àpáàdì.9.45 Àwọn àkọsílẹ̀ àtijọ́ ìwé Marku kan se àfikún ọ̀rọ̀ yìí àpáàdì. 46Níbi ti ‘kòkòrò wọn kì í kú, tí iná kì í sì í kú.’ 47 ojú rẹ kọsẹ̀, yọ ́ sọnù, ó sàn o wọ ìjọba Ọlọ́run pẹ̀ojú kan ju ó ojú méjì ó lọ sínú iná ̀run àpáàdì. 48 Níbi ti

" kòkòrò wọn í ,

iná í í .

49 9.49-50: Mt 5.13; Lk 14.34-35. Níbẹ̀ ni a ó ti fi iná dán ẹnìkọ̀̀kan .

50 9.50: 1Kọ 4.6; 1Tẹ 5.13. "Iyọ̀ dára, ṣùgbọ́n ó sọ adùn rẹ̀ , báwo ni ṣè padà un dùn? ni iyọ̀ nínú ara yín, ki máa gbé àlàáfíà pẹ̀ara yín."

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_21-26-40-