Publicidade

Malaquias 1

1 ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀: ̀rọ̀ Olúwa Israẹli láti ẹnu Malaki.

Ọlọ́run fẹ́ràn Jakọbu, o kórìíra Esau

2 "Èmí ti fẹ́ yín," ni Olúwa .

"Ṣùgbọ́n ̀yin béèrè , Báwo ni ìwọ ṣe fẹ́ wa?

"Esau í ha ṣe arákùnrin Jakọbu ?" ni Olúwa . "Síbẹ̀ èmi fẹ́ràn Jakọbu, 3 ṣùgbọ́n Esau ni mo kórìíra, mo ti sọ àwọn òkè ńlá rẹ̀ di aṣálẹ̀, mo fi ìní rẹ̀ fún àwọn akátá aginjù."

4 Edomu , "ó tilẹ̀ jẹ́ a run , àwa yóò padà , a ó tún ibùgbé náà kọ́."

Ṣùgbọ́n èyí ni ohun Olúwa àwọn ọmọ-ogun : "Àwọn kọ́, ṣùgbọ́n èmi yóò palẹ̀. Wọn yóò wọ́n ilẹ̀ búburú, àwọn ènìyàn wọ́n máa ń ìbínú Olúwa. 5 ̀yin yóò fi ojú yín i, ̀yin yóò , Títóbi ni Olúwa, títóbi rẹ̀ tayọ kọjá agbègbè Israẹli.

Ẹbọ àìmọ́

6 "Ọmọ a máa bu ̀wọ̀ fún baba rẹ̀, ọmọ ̀dọ̀ a máa bu ọlá fún olúwa rẹ̀. Ǹjẹ́ èmí jẹ́ baba, ọlá ó tọ́ mi ha ? èmi jẹ́ olúwa, ̀ó tọ́ mi ?" ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun .

"̀yin ni, ̀yin àlùfáà, ni ń gan orúkọ mi.

"Ṣùgbọ́n ̀yin béèrè , Báwo ni àwa ṣe gan orúkọ rẹ?

7 "̀yin gbé oúnjẹ àìmọ́ orí pẹpẹ mi.

"̀yin tún béèrè , Báwo ni àwa ṣe ṣe àìmọ́ ?

"Nípa sísọ tábìlì Olúwa di ̀gàn. 8 Nígbà ̀yin afọ́ẹran fún ìrúbọ, ṣé èyí ha burú ? Nígbà ̀yin fi amúnkùn ún àti aláìsàn ẹran ẹbọ, ṣé èyí ha burú gidigidi ? dán an , fi wọ́n ẹbọ àwọn baálẹ̀ yín! Ṣé inú rẹ̀ yóò dùn yín? Ṣé yóò gbà yín?" ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun .

9 "ìsinsin yìí, bẹ Ọlọ́run ó ṣàánú fún wa. Ṣùgbọ́n pẹ̀irú àwọn ẹbọ wọ̀nyí láti ọwọ́ yín , ṣé yóò gbà yín?" ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun .

10 "ò! Ẹnìkan ìbá jẹ́ láàrín yín ti yóò ìlẹ̀kùn tẹmpili, ba à ṣe iná asán lórí pẹpẹ mi mọ́! Èmi inú dídùn i yín," ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun , "bẹ́̀ ni èmi yóò gba ọrẹ kan lọ́wọ́ yín. 11 Orúkọ mi yóò tóbi láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, láti ìlà-oòrùn títí ó fi ìwọ̀-oòrùn. ibi gbogbo ni a ó ti tùràrí àti ọrẹ mímọ́ fún orúkọ mi, nítorí orúkọ mi tóbi láàrín àwọn orílẹ̀-èdè," ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun .

12 "Nítorí ̀yin ti sọ ́ di àìmọ́, nínú èyí , Tábìlì Olúwa di àìmọ́ àti èso rẹ̀,’ àní oúnjẹ rẹ̀ ni ohun ̀gàn. 13 ̀yin pẹ̀, ó, irú àjàgà kín ni èyí!̀yin yínmú i," Olúwa àwọn ọmọ-ogun .

"Nígbà ̀yin èyí ó fi ara pa, arọ àti ọlọkùnrùn ẹran fi ẹbọ, Èmi o ha gba èyí lọ́wọ́ yín?" ni Olúwa . 14 "Ṣùgbọ́n ègún ni fún ẹlẹ́tàn náà, ó ni akọ nínú ̀wọ́ ẹran rẹ̀, ó ṣe ìlérí láti fi lélẹ̀ ó fi ẹran lábùkù ẹbọ Olúwa; nítorí ọba ńlá ni Èmi," ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun , "̀ni orúkọ mi láàrín àwọn orílẹ̀-èdè.

Veja também

Publicidade
Malaquias
Ver todos os capítulos de Malaquias
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-