Publicidade

Mateus 10

Jesu rán àwọn méjìlá jáde

1 Jesu pe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ méjìlá ̀dọ̀; ó fún wọn àṣẹ láti ̀àìmọ́ jáde àti láti ṣe ìwòsàn ààrùn àti àìsàn gbogbo.

2 Orúkọ àwọn aposteli méjèèjìlá náà ni wọ̀nyí:

ẹni àkọ́kọ́ ni Simoni ẹni ti a ń ni Peteru àti arákùnrin rẹ̀ Anderu;

Jakọbu ọmọ Sebede àti arákùnrin rẹ̀ Johanu.

3 Filipi àti Bartolomeu;

Tomasi àti Matiu agbowó òde;

Jakọbu ọmọ Alfeu àti Taddeu;

4 Simoni ọmọ ẹgbẹ́ Sealoti, Judasi Iskariotu, ẹni ó da Jesu.

5 Àwọn méjèèjìlá wọ̀nyí ni Jesu ran, ó pàṣẹ fún wọn , "ṣe lọ ̀àwọn kèfèrí, ṣe wọ̀ ìlú àwọn ará Samaria. 6 kúkú tọ̀ àwọn àgùntàn ilé Israẹli ó lọ. 7 ̀yin ti ń lọ, máa wàásù yìí , Ìjọba ̀run dẹ̀dẹ̀.’ 8 máa ṣe ìwòsàn fún àwọn aláìsàn, si àwọn òkú dìde, sọ àwọn adẹ́tẹ̀ di mímọ́, máa àwọn ̀èṣù jáde. ̀fẹ́ ni ̀yin gbà á, ̀fẹ́ ni fi fún ni.

9 "ṣe wúrà tàbí fàdákà tàbí idẹ sínú àpò ìgbànú yín, 10 ṣe àpò fún ìrìnàjò yín, ṣe ̀méjì, tàbí bàtà, tàbí ̀; oúnjẹ oníṣẹ́ yẹ fún un. 11 Ìlúkílùú tàbí ìletòkíletò ̀yin wọ̀, ẹni ti ó yẹ níbẹ̀ , níbẹ̀ ni gbé nínú ilé rẹ̀ títí ̀yin yóò fi kúrò níbẹ̀. 12 Nígbà ̀yin wọ ilé kan, i wọn. 13 ilé náà yẹ, àlàáfíà yín ó sórí rẹ̀; ṣùgbọ́n yẹ, àlàáfíà yín ó padà sọ́dọ̀ yín. 14 ẹnikẹ́ni gbà yín, tàbí gba ̀rọ̀ yín, gbọn eruku ̀ṣẹ̀ yín sílẹ̀ ń kúrò ilé tàbí ìlú náà. 15 Lóòótọ́ ni mo fún yín, yóò sàn fún ìlú Sodomu àti Gomorra ọjọ́ ìdájọ́ ju àwọn ìlú náà lọ.

16 "ń rán yín lọ gẹ́gẹ́ àgùntàn sáàrín ìkookò. Nítorí náà, ìṣọ́ra ejò, ṣe onírẹ̀lẹ̀ àdàbà. 17 ṣọ́ra lọ́dọ̀ àwọn ènìyàn nítorí wọn yóò fi yín le àwọn ìgbìmọ̀ ìgbèríko lọ́wọ́ wọn yóò yín nínú Sinagọgu. 18 Nítorí orúkọ mi, a ó yín lọ síwájú àwọn baálẹ̀ àti àwọn ọba, ẹlẹ́rìí wọn àti àwọn aláìkọlà. 19 Nígbà wọ́n yín, ṣe ṣàníyàn ohun ó sọ tàbí ó ṣe sọ ́. ojú kan náà ni a ó fi ohun ̀yin yóò sọ fún yín. 20 Nítorí í ṣe ̀yin ni ó sọ ́, ṣe ̀Baba yín ń sọ̀rọ̀ nípasẹ̀ yín.

21 "Arákùnrin yóò fi arákùnrin fún pípa. Baba yóò fi àwọn ọmọ rẹ̀ fún ikú pa. Àwọn ọmọ yóò ṣọ̀tẹ̀ òbí wọn, wọn yóò a pa wọ́n. 22 Gbogbo ènìyàn yóò kórìíra yín nítorí mi, ṣùgbọ́n gbogbo ẹni ó dúró ṣinṣin òpin ni a ó gbàlà. 23 Nígbà wọn ṣe inúnibíni i yín ìlú kan, sálọ ìlú kejì. Lóòótọ́ ni mo fún yín, ̀yin í le la gbogbo ìlú Israẹli tán Ọmọ Ènìyàn .

24 "Akẹ́kọ̀́ í ju olùkọ́ rẹ̀ lọ, bẹ́̀ ni ọmọ ̀dọ̀ í ju ̀rẹ̀ lọ. 25 Ó tọ́ fún akẹ́kọ̀́ láti dàbí olùkọ́ rẹ̀ àti fún ọmọ ̀dọ̀ láti ̀rẹ̀. Nígbà wọ́n pe baálé ilé Beelsebulu, mélòó mélòó ni ti àwọn ènìyàn ilé rẹ̀!

26 "Nítorí náà, ṣe bẹ̀wọn, nítorí ohun ń bọ̀ í fi ara hàn, tàbí ohun ìkọ̀kọ̀ a mọ̀ ni gbangba. 27 Ohun mo fún yín òkùnkùn, òun ni sọ ìmọ́lẹ̀. Èyí mo sọ kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́ etí yín ni kéde rẹ́ lórí òrùlé. 28 ṣe bẹ̀àwọn ó le pa ara nìkan; ṣùgbọ́n wọn pa ̀. bẹ̀Ẹni ó le pa ̀àti ara run ̀run àpáàdì. 29 Ológoṣẹ́ méjì kọ́ ni à ń owó idẹ wẹ́wẹ́ kan? Síbẹ̀ ̀kan nínú wọn yóò ṣubú lu ilẹ̀ lẹ́yìn Baba yin. 30 Àti gbogbo irun orí yín ni a ti . 31 Nítorí náà, ṣe fòyà; ̀yin iye lórí ju ̀pọ̀ ológoṣẹ́ lọ.

32 "Ẹnikẹ́ni ó jẹ́wọ́ mi níwájú ènìyàn, òun náà ni èmi yóò jẹ́wọ́ rẹ̀ níwájú Baba mi ̀run. 33 Ṣùgbọ́n ẹni ó sẹ́ níwájú àwọn ènìyàn, òun náà ni èmi náà yóò sọ n mọ̀ níwájú Baba mi ̀run.

34 "ṣe mo àlàáfíà ayé, Èmi àlàáfíà ṣe idà. 35 Nítorí èmi láti ya

" ọmọkùnrin ipa baba rẹ̀,

ọmọbìnrin ipa ìyá rẹ̀,

àti aya ọmọ ìyakọ rẹ.

36 Ará ilé ènìyàn ni yóò máa ṣe ̀rẹ̀.’

37 "Ẹni ó fẹ́ baba rẹ̀ tàbí ìyá rẹ̀ lọ, yẹ tèmi, ẹni ó ba fẹ́ ọmọkùnrin tàbí ọmọbìnrin rẹ̀ lọ, yẹ tèmi. 38 Ẹni gbé àgbélébùú rẹ̀ ó tẹ̀mi yẹ tèmi. 39 Ẹni ó wa ̀rẹ̀ yóò sọ ́ , ṣùgbọ́n ẹni ó sọ ̀rẹ̀ nítorí tèmi ni yóò i.

40 "Ẹni ó gbà yín, ó gbà , ẹni ó gbà gba ẹni ó rán mi. 41 Ẹni ó ba gba wòlíì, nítorí ó jẹ́ wòlíì yóò jẹ èrè wòlíì, ẹni ó gba olódodo nítorí ti ó jẹ́ ènìyàn olódodo, yóò jẹ èrè olódodo. 42 Ẹnikẹ́ni ó fi ago omi tútù fún ̀kan nínú àwọn onírẹ̀lẹ̀ wọ̀nyí mu nítorí ó jẹ́ ọmọ-ẹ̀yìn mi, lóòótọ́ ni mo fún yín, pàdánù èrè rẹ̀."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-