Publicidade

Mateus 12

Olúwa ọjọ́ ìsinmi

1 àkókò náà ni Jesu ń la àárín oko ọkà kan lọ ọjọ́ ìsinmi, ebi ń pa àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀. Wọ́n bẹ̀rẹ̀ i ya orí ọkà, wọ́n ń jẹ ́. 2 Nígbà àwọn Farisi èyí. Wọ́n fún , "ó! Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ ń ṣe ohun òfin mu ọjọ́ ìsinmi."

3 Jesu dáhùn , "̀yin ha ka ohun Dafidi ṣe nígbà ebi ń pa á àti àwọn ó lọ́dọ̀ rẹ̀. 4 Ó wọ inú ilé Ọlọ́run, òun àti àwọn ènìyàn rẹ̀ jẹ àkàrà a sọ́tọ̀, èyí yẹ fún wọn láti jẹ, ṣe fún àwọn àlùfáà nìkan. 5 Tàbí ̀yin ti á nínú òfin ọjọ́ ìsinmi, àwọn àlùfáà ó tẹmpili ń ba ọjọ́ ìsinmi jẹ́ wọ́n láìjẹ̀bi. 6 Ṣùgbọ́n mo fún yín, ẹni ó pọ̀ ju tẹmpili lọ níhìn-ín. 7 ó jẹ́ mọ ìtumọ̀ ̀rọ̀ yìí, Àánú ni èmi ń fẹ́ í ṣe ẹbọ,̀yin aláìlẹ́ṣẹ̀ lẹ́bi. 8 Nítorí Ọmọ Ènìyàn jẹ́ Olúwa ọjọ́ ìsinmi."

9 Nígbà Jesu kúrò níbẹ̀ ó lọ Sinagọgu wọn, 10 ọkùnrin kan ọwọ́ rẹ̀ kan rọ níbẹ̀. Wọ́n ń ̀láti fi ̀sùn kan Jesu, wọ́n béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ , "Ǹjẹ́ ó tọ́ láti ènìyàn láradá ọjọ́ ìsinmi?"

11 Ó wọn lóhùn , "ó jẹ́ ẹnikẹ́ni nínú yín àgùntàn kan ṣoṣo, ó bọ́ sínú kòtò ọjọ́ ìsinmi, ǹjẹ́ yóò dìímú, ó á jáde. 12 Ǹjẹ́ mélòó mélòó ènìyàn iye lórí ju àgùntàn kan lọ! Nítorí náà ó yẹ láti ṣe rere ọjọ́ ìsinmi."

13 Nígbà náà, ó fún ọkùnrin náà , "Na ọwọ́ rẹ," òun ti án, ọwọ́ rẹ̀ bọ̀ ipò rẹ̀ gẹ́gẹ́ ọwọ́ èkejì. 14 Síbẹ̀ àwọn Farisi jáde lọ pe ìpàdé láti dìtẹ̀ un àti wọn yóò ṣe pa Jesu.

Ìránṣẹ́ Ọlọ́run yàn

15 Nígbà Jesu mọ̀, ó yẹra kúrò níbẹ̀. ̀pọ̀ ìjọ ènìyàn ń tọ̀ ́ lẹ́yìn, ó gbogbo àwọn aláìsàn láradá. 16 Ṣùgbọ́n ó kìlọ̀ fún wọn wọ́n ó ṣe fi òun hàn. 17 Èyí jẹ́ ìmúṣẹ àsọtẹ́lẹ̀ èyí wòlíì Isaiah sọ nípa rẹ̀ ,

18 "wo ìránṣẹ́ mi ẹni mo yàn.

Àyànfẹ́ mi ni ẹni inú mi dùn gidigidi;

èmi yóò fi ̀mi fún un.

Òun yóò ṣe ìdájọ́ àwọn kèfèrí.

19 Òun yóò , bẹ́̀ ni yóò kígbe;

ẹnikẹ́ni yóò gbọ́ ohùn rẹ ìgboro.

20 Koríko odò títẹ̀ kan ni òun yóò fọ́,

àti òwú-fìtílà ń tan an lọ lòun yóò fẹ́ pa.

Títí yóò fi ìdájọ́ ìṣẹ́gun.

21 orúkọ rẹ̀ ni gbogbo kèfèrí yóò fi ìrètí wọn ."

Jesu àti Beelsebulu

22 Nígbà náà ni wọ́n ọkùnrin kan ni ̀èṣù tọ̀ ́ , ó afọ́, ó tún ya odi. Jesu un láradá ó le sọ̀rọ̀, ó ríran. 23 Ẹnu ya gbogbo àwọn ènìyàn. Wọ́n , "Èyí ha jẹ́ Ọmọ Dafidi ?"

24 Ṣùgbọ́n nígbà àwọn Farisi gbọ́ èyí, wọ́n , "Nípa Beelsebulu nìkan, í ṣe ọba ̀èṣù ni ọkùnrin yìí fi àwọn ̀èṣù jáde."

25 Jesu ó mọ èrò wọn, ó fún wọn , "Ìjọbakíjọba ó yapa ara rẹ̀ yóò parun, ìlúkílùú tàbí ilékílé ó yapa ara rẹ̀ yóò dúró. 26 èṣù ń èṣù jáde, a jẹ́ , ó ń yapa ara rẹ̀. Ìjọba rẹ yóò ha ṣe le dúró? 27 Àti , bi èmi ń àwọn ̀èṣù jáde nípa Beelsebulu, nípa ta ni àwọn ènìyàn yín fi ń wọn jáde? Nítorí náà ni wọn yóò ṣe ṣe ìdájọ́ yín. 28 Ṣùgbọ́n ó jẹ́ nípa ̀Ọlọ́run ni èmi fi ń àwọn ̀èṣù jáde, a jẹ́ ìjọba Ọlọ́run ti yín.

29 "Tàbí, báwo ni ẹnikẹ́ni ṣe wọ ilé alágbára lọ ó ẹrù rẹ̀, ṣe ó kọ́kọ́ di alágbára náà? Nígbà náà ni ó ẹrù rẹ̀ lọ.

30 "Ẹni pẹ̀mi, òun lòdì mi, ẹni mi kójọpọ̀ ń fọ́nká. 31 Nítorí èyí, mo fún yín, gbogbo ̀ṣẹ̀ àti ̀rọ̀-òdì ni a yóò dárí rẹ̀ ènìyàn, ṣùgbọ́n ìsọ̀rọ̀-òdì ̀Mímọ́ ìdáríjì. 32 Ẹnikẹ́ni ó sọ̀rọ̀-òdì Ọmọ Ènìyàn, a ó dáríjì í, ṣùgbọ́n ẹni ó sọ ̀rọ̀-òdì ̀Mímọ́, a yóò dáríjì í, ìbá à ṣe ayé yìí tàbí ayé ń bọ̀.

33 "E sọ igi di rere, èso rẹ̀ a di rere tàbí sọ igi di búburú, èso rẹ a di búburú, nítorí nípa èso igi ni a ó fi mọ̀ igi. 34 ̀yin ọmọ paramọ́lẹ̀, báwo ni ̀yin jẹ búburú ṣe sọ̀rọ̀ rere? Ọkàn ènìyàn ni ó ń darí irú ̀rọ̀ ó jáde lẹ́nu rẹ̀. 35 Ẹni rere láti inú yàrá ìṣúra rere ọkàn rẹ̀ ohun rere jáde , àti ẹni búburú láti inú ìṣúra búburú ni; mu ohun búburú jáde . 36 Ṣùgbọ́n, mo sọ èyí fún yín, ̀yin yóò jíyìn gbogbo ìsọkúsọ yín ọjọ́ ìdájọ́. 37 Nítorí nípa ̀rọ̀ ẹnu yín ni a fi yin láre, nípa ̀rọ̀ ẹnu yín ni a ó fi yin lẹ́bi."

Àmì Jona

38 Nígbà náà ni, díẹ̀ nínú àwọn Farisi àti àwọn olùkọ́ òfin fún "Olùkọ́, àwa fẹ́ iṣẹ́ àmì kan lọ́dọ̀ rẹ̀".

39 Ó wọn lóhùn , "Ìran búburú àti ìran panṣágà ń béèrè àmì; ṣùgbọ́n àmì a ó fi fún un, ṣe àmì Jona wòlíì. 40 Jona ti gbé inú ẹja ńlá fún ̀sán mẹ́ta àti òru mẹ́ta, bẹ́̀ gẹ́gẹ́ ni ̀Ọmọ Ènìyàn yóò gbé inú ilẹ̀ fún ̀sán mẹ́ta àti òru mẹ́ta. 41 Àwọn ará Ninefe yóò dìde pẹ̀ìran yìí ọjọ́ ìdájọ́. Wọn yóò a lẹ́bi. Nítorí wọ́n ronúpìwàdà nípa ìwàásù Jona. Ṣùgbọ́n báyìí ẹni ó pọ̀Jona níhìn-ín yìí. 42 Ọbabìnrin gúúsù yóò dìde ọjọ́ ìdájọ́ ìran yìí yóò a lẹ́bi; nítorí ó láti ilẹ̀ ìkangun ayé láti gbọ́ ̀rọ̀ ọgbọ́n láti ẹnu Solomoni. Ṣùgbọ́n báyìí ẹni ó pọ̀Solomoni ń bẹ níhìn-ín yìí.

43 "Nígbà ̀búburú kan jáde lára ènìyàn, a máa rìn ibi gbígbẹ́, a máa ibi ìsinmi, i. 44 Nígbà náà ni ̀náà yóò , Èmi yóò padà ara ọkùnrin èmí ti .ó padà, ó ọkàn ọkùnrin náà ni òfìfo, a gbà á mọ́, a ṣe é ̀ṣọ́. 45 Nígbà náà ni yóò lọ, yóò ̀méje mìíràn pẹ̀ara rẹ̀, ó burú ju òun fúnra rẹ̀ lọ. Gbogbo wọn yóò inú rẹ̀, wọn yóò máa gbé ibẹ̀. Ìgbẹ̀yìn ọkùnrin náà a burú ju ìṣáájú rẹ̀ lọ. Bẹ́̀ gẹ́gẹ́ ni yóò fún ìran búburú yìí pẹ̀."

Ìyá Jesu àti àwọn arákùnrin rẹ̀

46 Nígbà ó ń sọ̀rọ̀ wọ̀nyí fún àwọn ènìyàn, ó, ìyá rẹ̀ àti àwọn arákùnrin rẹ̀ dúró lóde, wọ́n fẹ́ a sọ̀rọ̀. 47 Nígbà náà ni ẹnìkan fún un , "Ìyá rẹ àti àwọn arákùnrin rẹ ń dúró ́ lóde wọ́n ń fẹ́ sọ̀rọ̀."

48 Ó fún ni èsì , "Ta ni ìyá mi? Ta ni àwọn arákùnrin mi?" 49 Ó nawọ́ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ó , "ó, ìyá mi àti àwọn arákùnrin mi ni wọ̀nyí." 50 Nítorí náà, "Ẹnikẹ́ni ó ṣe ìfẹ́ Baba mi ń bẹ ̀run, ni arákùnrin mi àti arábìnrin mi àti ìyá mi."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-