Publicidade

Mateus 13

Òwe afúnrúgbìn

1 13.1-9: Mk 4.1-9; Lk 8.4-8; 5.1-3. ọjọ́ kan náà, Jesu kúrò ilé, ó jókòó etí Òkun. 2 ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn péjọ sọ́dọ̀ rẹ̀, bẹ́̀ ó fi bọ́ sínú ọkọ̀ ojú omi, ó jókòó, gbogbo ènìyàn dúró létí Òkun. 3 Nígbà náà ni ó fi ̀pọ̀lọpọ̀ òwe wọn sọ̀rọ̀, , "Àgbẹ̀ kan jáde lọ gbin irúgbìn sínú oko rẹ̀. 4 ó ti gbin irúgbìn náà, díẹ̀ bọ́ ̀̀, àwọn ẹyẹ , wọ́n jẹ ́. 5 Díẹ̀ bọ́ sórí ilẹ̀ orí àpáta, níbi ti erùpẹ̀ púpọ̀. Àwọn irúgbìn náà dàgbàsókè kíákíá, nítorí erùpẹ̀ pọ̀ lórí wọn. 6 Ṣùgbọ́n nígbà oòrùn gòkè, oòrùn gbígbóná wọn, gbogbo wọn rọ, wọ́n nítorí wọn ni gbòǹgbò. 7 Àwọn irúgbìn mìíràn bọ́ àárín ̀gún, ̀gún dàgbà, ó fún wọn pa. 8 Ṣùgbọ́n díẹ̀ bọ́ sórí ilẹ̀ rere, ó so èso, òmíràn ọgọ́rùn-ún, òmíràn ọgọ́tọ̀̀ta, òmíràn ọgbọọgbọ̀n, ni ìlọ́po èyí ti ó gbìn. 9 Ẹni ó létí, ó gbọ́."

10 13.10-13: Mk 4.10-12; Lk 8.9-10. Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ tọ̀ ́ , wọ́n i , "Èéṣe ìwọ ń fi òwe àwọn ènìyàn sọ̀rọ̀?"

11 Ó da wọn lóhùn , "̀yin ni a ti fi fún láti mọ ohun ìjìnlẹ̀ ìjọba ̀run, ṣùgbọ́n í ṣe fún wọn. 12 Ẹnikẹ́ni ó , òun ni a ó fún i, yóò lọ́pọ̀lọ́pọ̀. Ṣùgbọ́n lọ́wọ́ ẹni , ni a ó ti gbà èyí kékeré ó náà. 13 Ìdí nìyìí mo fi ń fi òwe wọn sọ̀rọ̀:

"ti , wọn ;

ti gbígbọ́ wọn gbọ́, bẹ́̀ ni wọn.

14 13.14-15: Isa 6.9-10; Mk 8.18; Jh 12.39-41; Ap 28.26-27. ara wọn ni a ti àsọtẹ́lẹ̀ wòlíì Isaiah ṣẹ:

" gbígbọ́ ̀yin yóò gbọ́ ṣùgbọ́n yóò yín;

̀yin yóò , ṣùgbọ́n ̀yin yóò mòye.

15 Nítorí àyà àwọn ènìyàn yìí sébọ́

etí wọn wúwo láti gbọ́

ojú wọn ni wọ́n

nítorí àwọn ba à fi ojú wọn

wọ́n ba à fi etí wọn gbọ́

wọn ba à fi àyà wọn mọ̀ òye,

wọn ba à yípadà, èmi ba à le wọn láradá.

16 13.16-17: Lk 10.23-24; Jh 8.56; Hb 11.13; 1Pt 1.10-12. Ṣùgbọ́n ìbùkún ni fún ojú yín, nítorí wọ́n ríran, àti fún etí yín, nítorí ti wọ́n gbọ́. 17 Lóòótọ́ ni mo fún yín, ̀pọ̀ àwọn wòlíì àti ènìyàn Ọlọ́run ti fẹ́ ohun ̀yin ti , ki wọ́n gbọ́ ohun ti gbọ́, ṣùgbọ́n ṣe é ṣe fún wọn.

18 13.18-23: Mk 4.13-20; Lk 8.11-15. "Nítorí náà, fi etí ohun òwe afúnrúgbìn túmọ̀ , 19 nígbà ẹnikẹ́ni gbọ́ ̀rọ̀ nípa ìjọba ̀run ṣùgbọ́n e, lẹ́yìn náà èṣù á , a gba èyí a fún ọkàn rẹ̀ kúrò. Èyí ni irúgbìn ti a fún ̀̀. 20 Ẹni ó gba irúgbìn ó bọ́ ilẹ̀ orí àpáta, ni ẹni ó gbọ́ ̀rọ̀ náà, lọ́gán, ó fi ayọ̀ gba ̀rọ̀ náà. 21 Ṣùgbọ́n nítorí gbòǹgbò, ó fún ìgbà díẹ̀; nígbà wàhálà àti inúnibíni dìde nítorí ̀rọ̀ náà ojú kan náà yóò kọsẹ̀. 22 Ẹni ó si gba irúgbìn ó bọ́ àárín ̀gún ni ẹni ó gbọ́ ̀rọ̀ náà, ṣùgbọ́n àwọn àníyàn ayé yìí, ìtànjẹ, ọrọ̀ fún ̀rọ̀ náà pa, ̀rọ̀ náà so èso nínú rẹ̀. 23 Ṣùgbọ́n ẹni ó gba irúgbìn ó bọ́ orí ilẹ̀ rere ni ẹni ó gbọ́ ̀rọ̀ náà, ó e; òun so èso òmíràn ọgọ́rọ̀̀rùn, òmíràn ọgọ́tọ̀̀ta, òmíràn ọgbọọgbọ̀n."

Òwe èpò àti alikama

24 13.24-30: Mk 4.26-29. Jesu tún pa òwe mìíràn fún wọn: "Ìjọba ̀run dàbí àgbẹ̀ kan ó gbin irúgbìn rere oko rẹ̀, 25 ṣùgbọ́n òru ọjọ́ kan, nígbà ó sùn, ̀rẹ̀ oko náà ó gbin èpò sáàrín alikama, ó tirẹ̀ lọ. 26 Nígbà alikama náà bẹ̀rẹ̀ dàgbà, ó so èso, nígbà náà ni èpò náà fi ara hàn.

27 "Àwọn ọmọ ̀dọ̀ àgbẹ̀ náà , wọ́n sọ fún un , ̀, irúgbìn rere kọ́ ni ìwọ ha gbìn oko rẹ ? Báwo ni èpò ṣe níbẹ̀ nígbà náà?

28 "Ó sọ fún wọn , ̀ni ó ṣe èyí.

"Àwọn ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀ tún i , Ǹjẹ́ ìwọ ha fẹ́ a fa èpò náà tu kúrò?

29 "Ó wọn lóhùn , Rárá, nítorí ̀yin ń tu èpò kúrò, ó tu alikama dànù pẹ̀rẹ̀. 30 jẹ́ àwọn méjèèjì máa dàgbà pọ̀, títí di àsìkò ìkórè. Èmi yóò sọ fún àwọn olùkórè náà láti kọ́kọ́ ṣa àwọn èpò kúrò wọ́n dìwọ́n ìtí, a sun wọn, wọ́n alikama sínú àká mi.’ "

Òwe hóró musitadi àti ìwúkàrà

31 13.31-32: Mk 4.30-32; Lk 13.18-19; Mt 17.20. Jesu tún pa òwe mìíràn fún wọn: "Ìjọba ̀run dàbí èso hóró musitadi, èyí ọkùnrin kan ó gbìn sínú oko rẹ̀. 32 ó tilẹ̀ jẹ́ èso ó kéré púpọ̀ láàrín èso rẹ̀, síbẹ̀ ó di ohun ̀gbìn ó tóbi jọjọ. Ó di igi bẹ́̀ àwọn ẹyẹ ojú ̀run , wọ́n fi ̀ka rẹ ṣe ibùgbé."

33 13.33: Lk 13.20-21; Ga 5.9; Gẹ 18.6. Ó tún pa òwe mìíràn fún wọn: "Ìjọba ̀run dàbí ìwúkàrà obìnrin kan ó mọ́ ìyẹ̀fun púpọ̀ títí gbogbo rẹ fi di wíwú."

34 13.34: Mk 4.33-34; Jh 10.6; 16.25. Òwe ni Jesu fi sọ nǹkan wọ̀nyí fún àwọn ènìyàn, òwe ni ó fi wọn sọ gbogbo ̀rọ̀ sọ. 35 13.35: Sm 78.2.̀rọ̀ a ti ẹnu àwọn wòlíì sọ ìmúṣẹ :

"Èmi yóò ya ẹnu mi láti fi òwe sọ̀rọ̀.

Èmi yóò sọ àwọn ohun ó fi ara sin láti ìpilẹ̀ṣẹ̀ ayé ."

Àlàyé òwe èpò àti alikama

36 Lẹ́yìn náà ó fi ̀pọ̀ ènìyàn sílẹ̀ lóde, ó wọ ilé lọ. Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ tọ̀ ́ , wọn , "Ṣàlàyé òwe èpò inú oko fún wa."

37 Ó wọn lóhùn , "Ọmọ Ènìyàn ni ẹni ó ń fúnrúgbìn rere. 38 Ayé ni oko náà; irúgbìn rere ni àwọn ènìyàn ti ìjọba ̀run. Èpò ni àwọn ènìyàn wọ́n jẹ́ ti èṣù, 39 ̀ó gbin àwọn èpò sáàrín alikama ni èṣù. Ìkórè ni òpin ayé, àwọn olùkórè àwọn angẹli.

40 "Gẹ́gẹ́ a ti èpò jọ, a sun ún nínú iná, bẹ́̀ gẹ́gẹ́ ni yóò ìgbẹ̀yìn ayé. 41 Ọmọ Ènìyàn yóò ran àwọn angẹli rẹ̀, wọn yóò gbogbo ohun ń ni dẹ́ṣẹ̀ kúrò ìjọba rẹ̀ àti gbogbo ènìyàn búburú. 42 Wọn yóò sọ wọ́n inú iná ìléru, níbi ti ẹkún òun ìpayínkeke yóò gbé . 43 Nígbà náà ni àwọn olódodo yóò máa ràn oòrùn ìjọba Baba wọn. Ẹni ó létí, jẹ́ ó gbọ́.

Òwe ìṣúra a fi pamọ́ sínú ilẹ̀ àti ohun ̀ṣọ́ olówó iyebíye

44 "Ìjọba ̀run dàbí ìṣúra kan a fi pamọ́ sínú oko. Nígbà ọkùnrin kan i ó tún fi í pamọ́. Nítorí ayọ̀ rẹ̀, ó ta gbogbo ohun ìní rẹ̀, ó ra oko náà.

45 "Bákan náà ni ìjọba ̀run dàbí oníṣòwò kan ó ń òkúta olówó iyebíye láti . 46 Nígbà ó ̀kan ó ni iye lórí, ó lọ láti ta gbogbo ohun ìní rẹ̀ láti le á.

Òwe ti àwọ̀n ẹja

47 13.47-50: Mt 13.40-42. "Bákan náà, a tún fi ìjọba ̀run àwọ̀n kan a sínú odò, ó onírúurú ẹja. 48 Nígbà àwọ̀n náà kún, àwọn apẹja á sókè etí bèbè Òkun, wọ́n jókòó, wọ́n ṣa àwọn èyí ó dára sínú apẹ̀rẹ̀, ṣùgbọ́n wọ́n da àwọn dára . 49 Bẹ́̀ gẹ́gẹ́ ni yóò ìgbẹ̀yìn ayé. Àwọn angẹli yóò láti ya àwọn ènìyàn búburú kúrò lára àwọn olódodo. 50 Wọn ó ju àwọn ènìyàn búburú sínú iná ìléru náà, ibi ti ẹkún àti ìpayínkeke yóò gbé ."

51 Jesu wọn léèrè , "Ǹjẹ́ gbogbo nǹkan wọ̀nyí yín."

Wọ́n dáhùn , "Bẹ́̀ ni, ó wa."

52 Ó fún wọn , "Nítorí náà ni olúkúlùkù olùkọ́ òfin ó ti di ọmọ-ẹ̀yìn ìjọba ̀run ṣe dàbí ọkùnrin kan í ṣe baálé ilé, ó ìṣúra tuntun àti èyí ó ti gbó jáde láti inú yàrá ìṣúra rẹ̀."

Wòlíì lọ́

53 13.53: Mt 7.28; 11.1; 19.1; 26.1. Lẹ́yìn ti Jesu ti parí òwe wọ̀nyí, ó ti ibẹ̀ kúrò. 54 13.54-58: Mk 6.1-6; Lk 4.16-30.Ó ìlú òun tìkára rẹ̀, níbẹ̀ ni ó ti ń kọ́ àwọn ènìyàn nínú Sinagọgu, ẹnu wọ́n. Wọ́n béèrè , "Níbo ni ọkùnrin yìí ti ọgbọ́n yìí àti iṣẹ́ ìyanu wọ̀nyí ? 55 í ha ṣe ọmọ gbẹ́nàgbẹ́ni èyí ? Ìyá rẹ̀ ha kọ́ ni à ń Maria ? Arákùnrin rẹ̀ ha kọ́ ni Jakọbu, Josẹfu, Simoni àti Judasi ? 56 Àwọn arábìnrin rẹ̀ gbogbo ha kọ́ ni ó ń wa gbé níhìn-ín yìí, nígbà náà níbo ni ọkùnrin yìí ti àwọn nǹkan wọ̀nyí?" 57 Inú wọn i.

Ṣùgbọ́n Jesu fún wọn , "Wòlíì a máa lọ́ibòmíràn, àfi ilé ara rẹ̀ àti ìlú ara rẹ̀ nìkan ni wòlíì ti lọ́."

58 Nítorí náà ṣe iṣẹ́ ìyanu kankan níbẹ̀, nítorí àìnígbàgbọ́ wọn.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-