Publicidade

Mateus 15

Ohun mímọ́ àti ohun àìmọ́

1 Nígbà náà àwọn Farisi àti àwọn olùkọ́ òfin tọ Jesu láti Jerusalẹmu, 2 wọn béèrè , "Èéṣe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ fi ń òfin àtayébáyé àwọn alàgbà? Nítorí wọn wẹ ọwọ́ wọn wọ́n jẹun!"

3 Jesu wọn lóhùn , "Èéha ṣe ̀yin fi òfin Ọlọ́run, nítorí àṣà yín? 4 Nítorí Ọlọ́run , Bọ̀wọ̀ fún Baba òun ìyá rẹ,àti , Ẹnikẹ́ni ó sọ ̀rọ̀-òdì baba tàbí ìyá rẹ̀, láti . 5 Ṣùgbọ́n ̀yin , ẹnikẹ́ni ó fún baba tàbí ìyá rẹ̀ , ̀bùn fún Ọlọ́run ni ohunkóhun ìwọ ìbá fi jèrè lára mi, 6 Òun bọ̀wọ̀ fún baba tàbí ìyá rẹ̀, ó bọ́; bẹ́̀ ni ̀yin sọ òfin Ọlọ́run di asán nípa àṣà yín. 7 ̀yin àgàbàgebè, òtítọ́ ni Wòlíì Isaiah sọtẹ́lẹ̀ nípa yín :

8 " Àwọn ènìyàn wọ̀nyí ń fi ẹnu lásán bu ọlá fún mi,

ṣùgbọ́n ọkàn wọn jìnnà réré mi.

9 Lásán ni ìsìn wọn;

nítorí wọ́n ń fi òfin ènìyàn kọ́ ni ̀kọ́.’ "

10 Jesu pe ̀pọ̀ ènìyàn ̀dọ̀ rẹ, ó , "tẹ́, jẹ́ nǹkan mo sọ yín. 11 Ènìyàn di aláìmọ́ nípa ohun ó wọ ẹnu ènìyàn, ṣùgbọ́n èyí ó ti ẹnu jáde ni ó sọ di aláìmọ́."

12 Nígbà náà, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ tọ̀ ́ , wọ́n fún un , "Ǹjẹ́ ìwọ mọ̀ inú àwọn Farisi lẹ́yìn wọ́n gbọ́ ̀rọ̀ ó sọ yìí?"

13 Jesu wọn lóhùn , "Gbogbo igi Baba mi ti ń bẹ ni ̀run gbìn ni á ó fàtu tigbòǹgbò tigbòǹgbò, 14 fi wọ́n sílẹ̀; afọ́ń fi ̀han afọ́ni wọ́n. afọ́ń fi ̀han afọ́, àwọn méjèèjì ni yóò jìn kòtò."

15 Peteru , "Ṣe àlàyé òwe yìí fún wa."

16 Jesu béèrè lọ́wọ́ wọn , "Èéha ṣe ìwọ fi jẹ́ aláìmòye síbẹ̀"? 17 "Ẹyin mọ̀ ohunkóhun ó gba ẹnu wọlé, yóò gba ti ̀oúnjẹ lọ, a yóò á jáde? 18 Ṣùgbọ́n ohun a ń sọ jáde láti ẹnu, inú ọkàn ni ó ti ń , èyí ni ó ń sọ ènìyàn di aláìmọ́. 19 Ṣùgbọ́n láti ọkàn ni èrò búburú ti , ìpànìyàn, panṣágà, àgbèrè, olè jíjà, irọ́ àti ̀rọ̀ ìbàjẹ́. 20 Àwọn a dárúkọ wọ̀nyí ni ó ń sọ ènìyàn di aláìmọ́. Ṣùgbọ́n láti jẹun láì wẹ ọwọ́, sọ ènìyàn di aláìmọ́."

21 Jesu ti ibẹ̀ kúrò lọ Tire àti Sidoni. 22 Obìnrin kan láti Kenaani, ó ń gbé ibẹ̀ ̀dọ̀ rẹ̀. Ó ń bẹ̀bẹ̀, ó kígbe , "Olúwa, ọmọ Dafidi, ṣàánú fún mi; ọmọbìnrin mi ̀èṣù ti ń a lóró gidigidi."

23 Ṣùgbọ́n Jesu fún un ìdáhùn, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ gbà á níyànjú , "obìnrin náà lọ, nítorí ó ń kígbe tọ̀ lẹ́yìn."

24 Ó dáhùn , "Àgùntàn ilẹ̀ Israẹli ó nìkan ni a rán mi ."

25 Obìnrin náà , ó wólẹ̀ níwájú rẹ̀, ó bẹ̀bẹ̀ i , "Olúwa ṣàánú fún mi."

26 Ó dáhùn , "tọ́ a gbé oúnjẹ àwọn ọmọ fún àwọn ajá."

27 Obìnrin náà , "Bẹ́̀ ni, síbẹ̀síbẹ̀ àwọn ajá a máa jẹ èrúnrún ó ti orí tábìlì olówó wọn bọ́ sílẹ̀."

28 Jesu sọ fún obìnrin náà , "Ìgbàgbọ́ ńlá ni tìrẹ! A ti dáhùn ìbéèrè rẹ." A ọmọbìnrin rẹ̀ láradá wákàtí kan náà.

Jesu bọ́ ẹgbàajì (4,000) ènìyàn

29 Jesu ti ibẹ̀ lọ Òkun Galili. Ó gun orí òkè, o jókòó níbẹ̀. 30 ̀pọ̀ àwọn ènìyàn tọ̀ ́ , àti àwọn arọ, afọ́, amúnkùn ún, odi àti ̀pọ̀ àwọn aláìsàn mìíràn. Wọ́n gbé wọn kalẹ̀ lẹ́sẹ̀ Jesu. Òun gbogbo wọn láradá. 31 Ẹnu ya ̀pọ̀ ènìyàn nígbà wọ́n àwọn odi ń sọ̀rọ̀, amúnkùn ún di alára pípé, arọ ó ń rìn àti àwọn afọ́ó ríran. Wọ́n ń fi ìyìn fún Ọlọ́run Israẹli.

32 Jesu pe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sọ́dọ̀, ó , "Àánú àwọn ènìyàn wọ̀nyí ṣe ; nítorí wọ́n ti níhìn-ín pẹ̀mi fún ọjọ́ mẹ́ta gbáko báyìí. Wọn tún oúnjẹ mọ́. Èmi fẹ́ wọn padà lébi, nítorí òyì kọ́ wọn lójú ̀."

33 Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn a lóhùn , "Níbo ni àwa yóò ti oúnjẹ ijù níhìn-ín yìí láti fi bọ́ ̀pọ̀ ènìyàn yìí?"

34 Jesu béèrè , "Ìṣù àkàrà mélòó ni ̀yin ?"

Wọ́n dáhùn , "Àwa ìṣù àkàrà méje pẹ̀àwọn ẹja wẹ́wẹ́ díẹ̀."

35 Jesu sọ fún gbogbo ènìyàn wọn jókòó lórí ilẹ̀. 36 Òun ìṣù àkàrà méje náà àti ẹja náà. Ó fi ọpẹ́ fún Ọlọ́run, ó wọ́n wẹ́wẹ́, ó fi wọ́n fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀. Wọ́n pín in fún àwọn ̀pọ̀ ènìyàn náà. 37 Gbogbo wọn jẹ, wọ́n . Lẹ́yìn náà, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn ṣa èyí tókù, ̀kún agbọ̀n méje ni èyí ṣẹ́jẹ́. 38 Gbogbo wọn jẹ́ ẹgbàajì (4,000) ọkùnrin láì kan àwọn obìnrin àti ọmọdé. 39 Lẹ́yìn náà, Jesu rán àwọn ènìyàn náà lọ ilé wọn, ó bọ́ sínú ọkọ̀, ó rékọjá lọ ẹkùn Magadani.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-