Publicidade

Mateus 22

Òwe àsè ìgbéyàwó

1 22.1-10: Lk 14.16-24. Jesu tún fi òwe sọ̀rọ̀ fún wọn : 2 "Ìjọba ̀run dàbí ọba kan ti ó múra àsè ìgbéyàwó ńlá fún ọmọ rẹ̀ ọkùnrin. 3 Ó rán àwọn ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀ lọ pe àwọn a ti tẹ́lẹ̀ ibi àsè ìgbéyàwó. Ṣùgbọ́n wọn fẹ́ .

4 "Lẹ́yìn náà ó tún rán àwọn ọmọ ̀dọ̀ mìíràn , sọ fún àwọn mo ti , mo ti ṣe àsè náà tán. A pa màlúù àti ẹran àbọ́pa mi, a ti ṣe ohun gbogbo tán, wa ibi àsè ìgbéyàwó.

5 "Ṣùgbọ́n àwọn wọ̀n-ọn-nì ó ránṣẹ́ lọ á si. Wọ́n ń iṣẹ́ wọn lọ, ̀kan ̀oko rẹ̀, òmíràn ibi òwò rẹ̀." 6 Àwọn ìyókù àwọn ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀, wọ́n ṣe àbùkù wọn, wọ́n wọ́n pa. 7 Ọba yìí bínú gidigidi, ó rán àwọn ọmọ-ogun rẹ̀, ó pa àwọn apànìyàn náà run, ó ìlú wọn.

8 "Nígbà náà ni ó fún àwọn ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀ , Àsè ìgbéyàwó ti ṣe tàn, ṣùgbọ́n àwọn a yẹ fún ọlá náà. 9 lọ ìgboro àti òpópónà pe ẹnikẹ́ni àsè ìgbéyàwó náà. 10 Nítorí náà, àwọn ọmọ ̀dọ̀ náà jáde lọ òpópónà. Wọ́n oríṣìíríṣìí ènìyàn wọ́n , àwọn ò dára àti àwọn dára, ilé àsè ìyàwó kún fún àlejò.

11 "Ṣùgbọ́n nígbà ọba wọlé láti wo àwọn àlejò a , ó ọkùnrin kan nínú wọn wọ aṣọ ìgbéyàwó. 12 Ọba bi í , ̀rẹ́, báwo ni ìwọ ṣe níhìn-ín yìí láìní aṣọ ìgbéyàwó?Ṣùgbọ́n ọkùnrin náà ìdáhùn kankan.

13 22.13: Mt 8.12; 13.42,50; 24.51; 25.30; Lk 13.28. "Nígbà náà ni ọba fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ , í tọwọ́ tẹsẹ̀, sọ ́ sínú òkùnkùn lóde níbi ẹkún àti ìpayínkeke .

14 "Nítorí ̀pọ̀ ni a ṣùgbọ́n díẹ̀ ni a yàn."

Sísan owó orí fún Kesari

15 22.15-22: Mk 12.13-17; Lk 20.20-26. 22.15: Mk 3.6; 8.15. Nígbà náà ni àwọn Farisi péjọpọ̀ láti ronú ̀wọn yóò gbà fi ̀rọ̀ ẹnu un. 16 Wọ́n rán àwọn ọmọ-ẹ̀yìn wọn pẹ̀àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Herodu lọ sọ́dọ̀ rẹ̀ , "Olùkọ́, àwa mọ̀ olóòtítọ́ ni ìwọ, ìwọ ń kọ́ni ̀Ọlọ́run òtítọ́. Bẹ́̀ ni ìwọ í wo ojú ẹnikẹ́ni; nítorí ìwọ í ṣe ojúsàájú ènìyàn. 17 Nísinsin yìí sọ fún wa, ni èrò rẹ? Ǹjẹ́ ó tọ́ láti san owó orí fún Kesari tàbí tọ́?"

18 Ṣùgbọ́n Jesu ti mọ èrò búburú inú wọn, ó , "̀yin àgàbàgebè, èéṣe ti ̀yin fi ń dán mi ? 19 fi owó ẹyọ a fi ń san owó orí kan hàn mi." Wọn dínárì kan fún un, 20 ó bi wọ́n , "Àwòrán ta ni èyí? Àkọlé ?"

21 22.21: Ro 13.7. Wọ́n dáhùn , "Ti Kesari ni."

"Nígbà náà ni ó fún wọn ," "fi èyí í ṣe ti Kesari fún Kesari, fi èyí ti ṣe ti Ọlọ́run fún Ọlọ́run."

22 Nígbà wọ́n gbọ́ èyí, ẹnu wọ́n. Wọ́n fi í sílẹ̀, wọ́n tiwọn lọ.

Ìgbéyàwó nígbà àjíǹde

23 22.23-33: Mk 12.18-27; Lk 20.27-38. 22.23: Ap 4.1-2; 23.6-10. Ṣùgbọ́n ọjọ́ kan náà, àwọn Sadusi wọ́n sọ si àjíǹde lẹ́yìn ikú tọ Jesu láti bi í ìbéèrè, 24 22.24: De 25.5.wọ́n , "Olùkọ́, Mose fún wa , ọkùnrin kan àìlọ́mọ, arákùnrin rẹ̀ ṣú aya rẹ̀ lópó, ó ọmọ fún un. 25 ó jẹ́ bẹ́̀, láàrín wa níhìn-ín yìí, ìdílé kan ó arákùnrin méje. Èyí èkínní nínú wọn gbéyàwó, lẹ́yìn náà ó àìlọ́mọ. Nítorí náà ìyàwó rẹ̀ di ìyàwó arákùnrin kejì. 26 Bẹ́̀ gẹ́gẹ́ arákùnrin èkejì náà tún láìlọ́mọ. A fi ìyàwó rẹ̀ fún arákùnrin ó tún tẹ̀e. Bẹ́̀ ni títí òun fi di ìyàwó ẹni keje. 27 Níkẹyìn obìnrin náà pàápàá . 28 Nítorí ó ti ṣe ìyàwó àwọn arákùnrin méjèèje, ìyàwó ta ni yóò jẹ́ àjíǹde òkú?"

29 Ṣùgbọ́n Jesu wọn lóhùn , "Àìmọ̀kan yín ni ó fa irú ìbéèrè báyìí. Nítorí ̀yin mọ Ìwé Mímọ́ àti agbára Ọlọ́run. 30 Nítorí àjíǹde ìgbéyàwó, a fi í fún ni ìyàwó. Gbogbo ènìyàn yóò dàbí àwọn angẹli ̀run. 31 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, nípa ti àjíǹde òkú, tàbí ̀yin mọ̀ Ọlọ́run ń yín sọ̀rọ̀ nígbà ti ó : 32 Èmi ni Ọlọ́run Abrahamu, Ọlọ́run Isaaki, àti Ọlọ́run Jakọbu.Ọlọ́run í ṣe Ọlọ́run òkú, ṣùgbọ́n àwọn alààyè."

33 22.33: Mt 7.28. Nígbà ti àwọn ènìyàn gbọ́ èyí ẹnu wọ́n ̀kọ́ rẹ.

Òfin ó ga jùlọ

34 22.34-40: Mk 12.28-34; Lk 20.39-40; 10.25-28. Nígbà ti wọ́n gbọ́ ó ti pa àwọn Sadusi lẹ́nu mọ́, àwọn Farisi ara wọn jọ. 35 22.35: Lk 7.30; 11.45; 14.3.̀kan nínú wọn ṣe amòfin dán an pẹ̀ìbéèrè yìí. 36 Ó , "Olùkọ́ èwo ni ó ga jùlọ nínú àwọn òfin?"

37 22.37: De 6.5. Jesu dáhùn , " Fẹ́ Olúwa Ọlọ́run rẹ pẹ̀gbogbo ọkàn rẹ, gbogbo ̀rẹ àti gbogbo inú rẹ.38 Èyí ni òfin àkọ́kọ́ àti èyí ó tóbi jùlọ. 39 Èkejì ó tún dàbí rẹ̀ , Fẹ́ràn ọmọnìkejì rẹ gẹ́gẹ́ ara rẹ. 40 Lórí àwọn òfin méjèèjì yìí ni gbogbo òfin àti àwọn wòlíì rọ̀ mọ́."

Ọmọ ta ni Kristi?

41 22.41-46: Mk 12.35-37; Lk 20.41-44. àwọn Farisi ti ara wọn jọ, Jesu béèrè lọ́wọ́ wọn , 42 "ni nípa Kristi? Ọmọ ta ni òun ń ṣe?"

Wọ́n dáhùn , "Ọmọ Dafidi."

43 Ó fún wọn , "lo Dafidi, ̀ń darí, é Olúwa? Nítorí ó ,

44 " Olúwa sọ fún Olúwa mi ,

"Jókòó ọwọ́ ̀tún mi

títí èmi yóò fi fi àwọn ̀rẹ

abẹ́ ẹsẹ̀ rẹ." 

45 Ǹjẹ́ Dafidi é ni Olúwa,báwo ni òun ṣe jẹ́ ọmọ rẹ̀?" 46 22.46: Mk 12.34; Lk 20.40.ẹnìkan ó sọ ̀rọ̀ kan ni ìdáhùn, tún ẹni ó tún i léèrè ohun kan mọ́ láti ọjọ́ náà mọ́.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_21-26-40-