Pular para o conteúdo
Publicidade

Mateus 25

Òwe tálẹ́ǹtì

14 25.14-30: Lk 19.12-28. "A tún fi ìjọba ̀run ọkùnrin kan ó ń lọ ìrìnàjò. Ó pe àwọn ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀, ó ohun ìní rẹ̀ fún wọn. 15 Ó fún ̀kan ni tálẹ́ǹtì márùn-ún, ó fún èkejì ni tálẹ́ǹtì méjì, ó fún ̀kẹta ni tálẹ́ǹtì kan, ó fún olúkúlùkù gẹ́gẹ́ agbára rẹ̀ ti mọ, ó lọ ìrìnàjò tirẹ̀. 16 Ọkùnrin ó gba tálẹ́ǹtì márùn-ún bẹ̀rẹ̀ lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀ láti fi owó náà ṣòwò. Láìpẹ́, ó jèrè márùn-ún mìíràn. 17 Ọkùnrin ó gba tálẹ́ǹtì méjì náà fi tirẹ̀ ṣòwò. Láìpẹ́, ó jèrè tálẹ́ǹtì méjì mìíràn. 18 Ṣùgbọ́n ọkùnrin ò gba tálẹ́ǹtì kan, ó wa ihò ilẹ̀, ó bo owó ̀mọ́ ibẹ̀.

19 25.19: Mt 18.23. "Lẹ́yìn ọjọ́ pípẹ́, olúwa àwọn ọmọ ̀dọ̀ láti àjò rẹ̀. Ó wọ́n jọ láti wọn ṣírò owó rẹ̀. 20 Ọkùnrin ó gba tálẹ́ǹtì márùn-ún, márùn-ún mìíràn padà , ó , Olúwa, ìwọ ti fi tálẹ́ǹtì márùn-ún fún mi, mo ti jèrè márùn-ún mìíràn pẹ̀rẹ̀.’

21 25.21: Lk 16.10; Mt 24.45. "Olúwa rẹ̀ fún un , O ṣeun ìwọ ọmọ ̀dọ̀ rere àti olóòtítọ́: ìwọ ṣe olóòtítọ́ nínú ohun díẹ̀, èmi yóò fi ́ ṣe olórí ohun púpọ̀, bọ́ sínú ayọ̀ olúwa rẹ.

22 "Èyí ó gba tálẹ́ǹtì méjì Olúwa, ìwọ fún mi tálẹ́ǹtì méjì láti , èmi ti jèrè tálẹ́ǹtì méjì mìíràn.

23 "Olúwa rẹ̀ fún un , O ṣeun, ìwọ ọmọ ̀dọ̀ rere àti olóòtítọ́. Ìwọ ti jẹ́ olóòtítọ́ nínú ohun díẹ̀, èmi yóò fi ṣe olórí ohun púpọ̀. Ìwọ bọ́ sínú ayọ̀ olúwa rẹ.

24 "Níkẹyìn, ọkùnrin a fún tálẹ́ǹtì kan , ó , Olúwa, mo mọ̀ òǹrorò ènìyàn ni ìwọ ń ṣe ìwọ ń kórè níbi ìwọ gbìn , ìwọ ń kójọ níbi ìwọ ó . 25 Èmi bẹ̀, mo lọ pa tálẹ́ǹtì rẹ mọ́ sínú ilẹ̀. ó, nǹkan rẹ nìyìí.

26 "Ṣùgbọ́n olúwa rẹ̀ dáhùn , Ìwọ ọmọ ̀dọ̀ búburú, ìwọ mọ̀ èmi ń kórè níbi èmi fúnrúgbìn , èmi ń kójọ níbi èmi fọ́nká . 27 Nígbà náà ìwọ ìbá kúkú fi owó mi ilé ìfowópamọ́ èmi èmi ìbá le gba owó mi pẹ̀èrè.

28 " Ó pàṣẹ a gba tálẹ́ǹtì náà lọ́wọ́ rẹ̀, a fún ọkùnrin ó tálẹ́ǹtì mẹ́wàá. 29 Nítorí ẹnikẹ́ni ó a ó fún i, yóò tún lọ́pọ̀lọ́pọ̀. Ṣùgbọ́n láti ọwọ́ ẹni ni a ó ti gbà èyí ó . 30 Nítorí ìdí èyí, gbé aláìlérè ọmọ ̀dọ̀, ú sínú òkùnkùn lóde, ibẹ̀ ni ̀kún òun ìpayínkeke yóò gbé .

Veja também