Publicidade

Mateus 25

Òwe àwọn wúńdíá mẹ́wàá

1 "Nígbà náà ni ó fi ìjọba ̀run àwọn wúńdíá mẹ́wàá. Ti wọ́n gbé fìtílà wọn láti lọ pàdé ọkọ ìyàwó. 2 Márùn-ún nínú wọn jẹ́ ọlọ́gbọ́n, márùn-ún nínú wọn ni wọ́n jẹ́ aláìgbọ́n. 3 Àwọn wọ́n jẹ́ aláìgbọ́n gbé fìtílà wọn ṣùgbọ́n wọn epo kankan lọ́wọ́. 4 Àwọn ọlọ́gbọ́n epo sínú kólòbó lọ́wọ́ pẹ̀fìtílà wọn. 5 Nígbà ọkọ ìyàwó pẹ́, gbogbo wọn tòògbé wọn sùn.

6 "Nígbà ó di ̀gànjọ́, igbe ta sókè, ó, ọkọ ìyàwó ń bọ̀, jáde sóde láti pàdé rẹ̀.’

7 "Nígbà náà ni àwọn wúńdíá tají, wọ́n tún fìtílà wọn ṣe. 8 Àwọn aláìgbọ́n márùn-ún epo rárá bẹ àwọn ọlọ́gbọ́n wọn fún àwọn nínú èyí wọ́n nítorí fìtílà wọn ń lọ.

9 "Ṣùgbọ́n àwọn ọlọ́gbọ́n márùn-ún dáhùn , bẹ́̀ kọ́; ó ba à ṣe aláìtó fún àwa àti ̀yin, kúkú tọ àwọn ń á lọ, fún ara yín.

10 "àsìkò wọ́n lọ ra epo tiwọn, ni ọkọ ìyàwó . Àwọn wúńdíá ó múra tán a wọlé ibi àsè ìgbéyàwó, lẹ́yìn náà, a ti ìlẹ̀kùn.

11 "ìkẹyìn ni àwọn wúńdíá márùn-ún ìyókù , wọ́n ń , Olúwa, Olúwa, ṣílẹ̀kùn fún wa.

12 "Ṣùgbọ́n ọkọ ìyàwó dáhùn , Lóòótọ́ ni mo fún yín èmi mọ̀ yín .

13 "Nítorí náà, máa ṣọ́. Nítorí ̀yin mọ ọjọ́ tàbí wákàtí Ọmọ Ènìyàn yóò .

Òwe tálẹ́ǹtì

14 "A tún fi ìjọba ̀run ọkùnrin kan ó ń lọ ìrìnàjò. Ó pe àwọn ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀, ó ohun ìní rẹ̀ fún wọn. 15 Ó fún ̀kan ni tálẹ́ǹtì márùn-ún, ó fún èkejì ni tálẹ́ǹtì méjì, ó fún ̀kẹta ni tálẹ́ǹtì kan, ó fún olúkúlùkù gẹ́gẹ́ agbára rẹ̀ ti mọ, ó lọ ìrìnàjò tirẹ̀. 16 Ọkùnrin ó gba tálẹ́ǹtì márùn-ún bẹ̀rẹ̀ lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀ láti fi owó náà ṣòwò. Láìpẹ́, ó jèrè márùn-ún mìíràn. 17 Ọkùnrin ó gba tálẹ́ǹtì méjì náà fi tirẹ̀ ṣòwò. Láìpẹ́, ó jèrè tálẹ́ǹtì méjì mìíràn. 18 Ṣùgbọ́n ọkùnrin ò gba tálẹ́ǹtì kan, ó wa ihò ilẹ̀, ó bo owó ̀mọ́ ibẹ̀.

19 "Lẹ́yìn ọjọ́ pípẹ́, olúwa àwọn ọmọ ̀dọ̀ láti àjò rẹ̀. Ó wọ́n jọ láti wọn ṣírò owó rẹ̀. 20 Ọkùnrin ó gba tálẹ́ǹtì márùn-ún, márùn-ún mìíràn padà , ó , Olúwa, ìwọ ti fi tálẹ́ǹtì márùn-ún fún mi, mo ti jèrè márùn-ún mìíràn pẹ̀rẹ̀.’

21 "Olúwa rẹ̀ fún un , O ṣeun ìwọ ọmọ ̀dọ̀ rere àti olóòtítọ́: ìwọ ṣe olóòtítọ́ nínú ohun díẹ̀, èmi yóò fi ́ ṣe olórí ohun púpọ̀, bọ́ sínú ayọ̀ olúwa rẹ.

22 "Èyí ó gba tálẹ́ǹtì méjì Olúwa, ìwọ fún mi tálẹ́ǹtì méjì láti , èmi ti jèrè tálẹ́ǹtì méjì mìíràn.

23 "Olúwa rẹ̀ fún un , O ṣeun, ìwọ ọmọ ̀dọ̀ rere àti olóòtítọ́. Ìwọ ti jẹ́ olóòtítọ́ nínú ohun díẹ̀, èmi yóò fi ṣe olórí ohun púpọ̀. Ìwọ bọ́ sínú ayọ̀ olúwa rẹ.

24 "Níkẹyìn, ọkùnrin a fún tálẹ́ǹtì kan , ó , Olúwa, mo mọ̀ òǹrorò ènìyàn ni ìwọ ń ṣe ìwọ ń kórè níbi ìwọ gbìn , ìwọ ń kójọ níbi ìwọ ó . 25 Èmi bẹ̀, mo lọ pa tálẹ́ǹtì rẹ mọ́ sínú ilẹ̀. ó, nǹkan rẹ nìyìí.

26 "Ṣùgbọ́n olúwa rẹ̀ dáhùn , Ìwọ ọmọ ̀dọ̀ búburú, ìwọ mọ̀ èmi ń kórè níbi èmi fúnrúgbìn , èmi ń kójọ níbi èmi fọ́nká . 27 Nígbà náà ìwọ ìbá kúkú fi owó mi ilé ìfowópamọ́ èmi èmi ìbá le gba owó mi pẹ̀èrè.

28 " Ó pàṣẹ a gba tálẹ́ǹtì náà lọ́wọ́ rẹ̀, a fún ọkùnrin ó tálẹ́ǹtì mẹ́wàá. 29 Nítorí ẹnikẹ́ni ó a ó fún i, yóò tún lọ́pọ̀lọ́pọ̀. Ṣùgbọ́n láti ọwọ́ ẹni ni a ó ti gbà èyí ó . 30 Nítorí ìdí èyí, gbé aláìlérè ọmọ ̀dọ̀, ú sínú òkùnkùn lóde, ibẹ̀ ni ̀kún òun ìpayínkeke yóò gbé .

Àwọn àgùntàn àti ewúrẹ́

31 "Ṣùgbọ́n nígbà ti Ọmọ Ènìyàn yóò nínú ògo rẹ̀ pẹ̀gbogbo àwọn angẹli rẹ̀ nígbà náà ni yóò jókòó lórí ìtẹ́ ògo ̀run. 32 Gbogbo orílẹ̀-èdè ni a ó kójọ níwájú rẹ̀, òun yóò ya àwọn ènìyàn ayé ̀tọ̀ gẹ́gẹ́ olùṣọ́-àgùntàn ṣe é ya àgùntàn kúrò lára àwọn ewúrẹ́. 33 Òun yóò fi àgùntàn ọwọ́ ̀tún àti ewúrẹ́ ọwọ́ òsì.

34 "Nígbà náà ni ọba yóò fún àwọn ó lọ́wọ́ ̀tún , , ̀yin Baba mi ti bùkún fún, jogún ìjọba a ti pèsè fún yín láti ìpilẹ̀ṣẹ̀ ayé. 35 Nítorí ebi pa mi, ̀yin fún mi oúnjẹ, òǹgbẹ gbẹ , ̀yin fún mi omi. Mo jẹ́ àlejò, ̀yin sínú ilé yín. 36 Mo ìhòhò, ̀yin daṣọ . Nígbà mo ṣe àìsàn ṣe ìtójú mi, àti ìgbà mo ọgbà ̀wọ̀n ̀yin bẹ̀ .

37 "Nígbà náà ni àwọn olódodo yóò fèsì , Olúwa, nígbà wo ni àwa ebi ń pa ́, a fún oúnjẹ? Tàbí òǹgbẹ ń gbẹ ́ a fún ohun mímu? 38 Tàbí o jẹ́ àlejò a gbà ó sínú ilé wa? Tàbí o ìhòhò, a daṣọ ́? 39 Nígbà wo ni a tilẹ̀ i o ṣe àìsàn, tàbí o ọgbà ̀wọ̀n, a bẹ̀ ́ ?

40 "Ọba náà yóò dáhùn yóò fún wọn , Lóòótọ́ ni mo fún yín níwọ̀n ìgbà ̀yin ṣe nǹkan wọ̀nyí fún àwọn arákùnrin mi yìí o kéré lọ, ̀ ń ṣe wọn fún mi ni.

41 "Nígbà náà ni yóò sọ fún àwọn ọwọ́ òsì , kúrò lọ́dọ̀ mi, ̀yin ẹni ègún, sínú iná àìnípẹ̀kun a ti tọ́fún èṣù àti àwọn angẹli rẹ̀. 42 Nítorí ebi pa mi, ̀yin tilẹ̀ bọ́ mi, òrùngbẹ gbẹ mi, tilẹ̀ fún mi omi láti mu. 43 Mo jẹ́ àlejò, ̀yin tilẹ̀ gbà mi sílé. Mo ìhòhò, ̀yin fi aṣọ mi. Mo ṣàìsàn, mo lọ́gbà ̀wọ̀n, ̀yin bẹ̀ .

44 "Nígbà náà àwọn pẹ̀yóò dáhùn , Olúwa, nígbà wo ni àwa , ebi ń pa ́ tàbí òǹgbẹ ń gbẹ ́, tàbí o ṣàìsàn, tàbí o lọ́gbà ̀wọ̀n, a ràn ́ lọ́wọ́?’

45 "Nígbà náà àwọn yóò dáhùn , Lóòótọ́ ni mo fún , nígbà ̀yin ti kọ̀ láti ran ̀kan nínú àwọn ó kéré lọ́wọ́ nínú arákùnrin mi, ̀yin kọ̀ láti ṣe ìrànlọ́wọ́ fún mi ni.

46 "Nígbà náà wọn yóò kọjá lọ sínú ìyà àìnípẹ̀kun, ṣùgbọ́n àwọn olódodo yóò lọ ìyè àìnípẹ̀kun."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-