Publicidade

Mateus 27

Judasi lọ pokùnso

1 òwúrọ̀, gbogbo àwọn olórí àlùfáà àti àwọn àgbàgbà Júù tún padà láti gbìmọ̀ wọn yóò ti ṣe pa Jesu. 2 Lẹ́yìn èyí, wọ́n fi ̀wọ̀n é, wọ́n jọ̀wọ́ rẹ̀ fún Pilatu i ṣe gómìnà.

3 Nígbà Judasi, ẹni ó fi í hàn, i a ti a lẹ́bi ikú, ó ọkàn rẹ̀ padà, ó káàánú nípa ohun ó ṣe. Ó ọgbọ̀n owó fàdákà ó gba náà fún àwọn olórí àlùfáà àti àwọn àgbàgbà Júù. 4 Ó , "Mo ti ṣẹ̀ nítorí mo ti ta ̀jẹ̀ aláìlẹ́ṣẹ̀ sílẹ̀."

Wọ́n a lóhùn pẹ̀ìbínú , "Èyí kàn ! Wàhálà tìrẹ ni!"

5 Nígbà náà ni Judasi da owó náà sílẹ̀ nínú tẹmpili. Ó jáde, ó lọ pokùnso.

6 Àwọn olórí àlùfáà owó náà. Wọ́n , "Àwa fi owó yìí sínú owó ìkójọpọ̀. ìwọ̀n ìgbà ó lòdì òfin wa nítorí owó ̀jẹ̀ ni." 7 Wọ́n gbìmọ̀, wọ́n fi ra ilẹ̀ amọ̀kòkò, láti máa sin òkú àwọn àjèjì nínú rẹ̀. 8 Ìdí nìyìí à ń pe ibi ìsìnkú náà "Ilẹ̀ ̀jẹ̀" títí di òní. 9 Èyí jẹ́ ìmúṣẹ èyí a ti sọtẹ́lẹ̀ láti ẹnu wòlíì Jeremiah , "Wọ́n ọgbọ̀n owó fàdákà àwọn ènìyàn Israẹli díye e. 10 Wọ́n fi ra ilẹ̀ kan lọ́wọ́ àwọn amọ̀kòkò gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ."

Jesu níwájú Pilatu

11 Nígbà náà ni Jesu dúró níwájú baálẹ̀ láti gba ìdájọ́. Baálẹ̀ béèrè , "Ṣe ìwọ ni ọba àwọn Júù?"

Jesu dáhùn , "Bẹ́̀ ni, nítorí ìwọ i."

12 Ṣùgbọ́n nígbà àwọn olórí àlùfáà àti àwọn àgbàgbà Júù fi gbogbo ̀sùn wọn kàn án, Jesu dáhùn kan. 13 Nígbà náà ni Pilatu, béèrè lọ́wọ́ Jesu , "Àbí ìwọ gbọ́ ̀wọn ń nípa rẹ ni?" 14 Jesu tún dáhùn kan. Èyí ya baálẹ̀ lẹ́nu.

15 Ó jẹ́ àṣà gómìnà láti ̀kan nínú àwọn ẹlẹ́wọ̀n Júù sílẹ̀ lọ́dọọdún, àsìkò àjọ̀dún ìrékọjá. Ẹnikẹ́ni àwọn ènìyàn ti fẹ́ ni. 16 àsìkò náà ̀daràn paraku kan nínú ̀wọ̀n à ń Jesu Baraba. 17 ̀pọ̀ ènìyàn ti péjọ síwájú ilé Pilatu lówúrọ̀ ọjọ́ náà, ó béèrè lọ́wọ́ wọn , "Ta ni ̀yin ń fẹ́ n sílẹ̀ fún yín, Baraba tàbí Jesu, ẹni ń jẹ́ Kristi?" 18 Òun ti mọ̀ nítorí ìlara ni wọn fi á òun lọ́wọ́.

19 Pilatu ti ṣe jókòó lórí ìtẹ́ ìdájọ́ rẹ̀, ìyàwó rẹ̀ ránṣẹ́ i , "ṣe ohun kankan ṣe pẹ̀ọkùnrin aláìṣẹ̀ náà. Nítorí mo jìyà ohun púpọ̀ lójú àlá mi lónìí nítorí rẹ̀."

20 Ṣùgbọ́n àwọn olórí àlùfáà àti àwọn àgbàgbà Júù rọ àwọn ènìyàn, láti béèrè a Baraba sílẹ̀, a béèrè ikú fún Jesu.

21 Nígbà Pilatu tún béèrè lọ́wọ́ wọn , "Èwo nínú àwọn méjèèjì yìí ni ̀ ń fẹ́ n sílẹ̀ fún yín?"

Àwọn ènìyàn kígbe padà , "Baraba!"

22 Pilatu béèrè , "ni èmi ṣe Jesu ẹni ti a ń Kristi?"

Gbogbo wọn tún kígbe , "Kàn án mọ́ àgbélébùú!"

23 Pilatu béèrè , "Nítorí ni? ṣe ó burú?"

Wọ́n kígbe sókè , "Kàn án mọ́ àgbélébùú! Kàn án mọ́ àgbélébùú!"

24 Nígbà Pilatu i òun tún nǹkan kan ṣe mọ́, àti rògbòdìyàn ti ń bẹ̀rẹ̀, ó béèrè omi, ó wẹ ọwọ́ rẹ̀ níwájú ̀pọ̀ ènìyàn, ó , "Ọrùn mọ́ nípa ̀jẹ̀ ọkùnrin yìí. ̀yin fúnra yín, bojútó o!"

25 Gbogbo àgbájọ náà , "̀jẹ̀ rẹ̀ lórí wa, àti orí àwọn ọmọ wa!"

26 Nígbà náà ni Pilatu Baraba sílẹ̀ fún wọn. Lẹ́yìn òun ti na Jesu tán, ó fi í wọn lọ́wọ́ láti un lọ kàn mọ́ àgbélébùú.

Àwọn ọmọ-ogun na Jesu

27 Nígbà náà ni àwọn ọmọ-ogun gómìnà Jesu lọ gbọ̀ngàn ìdájọ́ wọ́n gbogbo ẹgbẹ́ ọmọ-ogun í. 28 Wọ́n Jesu ìhòhò, wọ́n wọ̀ ́ aṣọ òdòdó, 29 wọ́n hun adé ̀gún. Wọ́n fi e lórí. Wọ́n fi ̀ọwọ́ ̀tún rẹ̀ gẹ́gẹ́ ̀ọba. Wọ́n wólẹ̀ níwájú rẹ̀, wọ́n fi í ṣe ẹlẹ́, "Kábíyèsí, ọba àwọn Júù!" 30 Wọ́n tu itọ́ i lójú àti ara, wọ́n gba ̀wọ́n án lórí. 31 Nígbà wọ́n fi ṣẹ̀sín tán, wọ́n bọ́ aṣọ ara rẹ̀. Wọ́n tún fi aṣọ tirẹ̀ wọ̀ ́. Wọ́n un jáde láti kàn án mọ́ àgbélébùú.

A kan Jesu mọ́ àgbélébùú

32 wọ́n ti ń jáde, wọ́n ọkùnrin kan ará Kirene à ń Simoni. Wọ́n ọkùnrin náà túláàsì láti ru àgbélébùú Jesu. 33 Wọ́n jáde lọ àdúgbò kan à ń Gọlgọta (èyí í ṣe "Ibi Agbárí"). 34 Níbẹ̀ ni wọn ti fún un ni ọtí wáìnì ó egbòogi nínú láti mu. Ṣùgbọ́n nígbà ó tọ́ , ó kọ̀ láti mu ún. 35 Lẹ́yìn wọ́n ti kàn án mọ́ àgbélébùú, wọ́n dìbò láti pín aṣọ rẹ̀ láàrín ara wọn. 36 Nígbà náà ni wọ́n jókòó i . Wọ́n ń ṣọ́ níbẹ̀. 37 òkè orí rẹ̀, wọ́n kọ ohun kan ó báyìí :

"Èyí ni Jesu, Ọba àwọn Júù."

síbẹ̀. 38 Wọ́n kan àwọn olè méjì pẹ̀rẹ̀ òwúrọ̀ náà. ̀kan ọwọ́ ̀tún, àti èkejì ọwọ́ òsì rẹ̀. 39 Àwọn ń kọjá lọ ń u. Wọ́n ń mi orí wọn : 40 "Ìwọ yóò tẹmpili, ìwọ yóò tún un mọ ọjọ́ kẹta. ó jẹ́ Ọmọ Ọlọ́run ni ìwọ, sọ̀kalẹ̀ láti orí igi àgbélébùú, ó gba ara rẹ !"

41 Bákan náà àwọn olórí àlùfáà pẹ̀àwọn akọ̀òfin àti àwọn àgbàgbà Júù fi í ṣe ẹlẹ́. 42 Wọ́n kẹ́gàn rẹ̀ , "Ó gba àwọn ẹlòmíràn , gba ara rẹ̀. Ìwọ ọba àwọn Israẹli? Sọ̀kalẹ̀ láti orí àgbélébùú nísinsin yìí, àwa yóò gbà ́ gbọ́. 43 Ó gba Ọlọ́run gbọ́, jẹ́ Ọlọ́run gbà á ìsinsin yìí òun fẹ́ . Ǹjẹ́ òun , èmi ni Ọmọ Ọlọ́run?" 44 Bákan náà, àwọn olè a kàn mọ́ àgbélébùú pẹ̀rẹ̀ fi í ṣe ẹlẹ́.

Ikú Jesu

45 Láti wákàtí kẹfà ni òkùnkùn fi ṣú bo gbogbo ilẹ̀ títí wákàtí kẹsànán ọjọ́. 46 Níwọ̀n wákàtí kẹsànán Jesu kígbe ohùn rara , "Eli, Eli, lama sabakitani" (èdè Heberu). Ìtumọ̀ èyí í ṣe, "Ọlọ́run mi, Ọlọ́run mi, èéṣe ìwọ fi kọ̀ sílẹ̀?"

47 ̀rọ̀ rẹ̀ díẹ̀ nínú àwọn ẹni ń wòran, nígbà wọ́n gbọ́ ̀rọ̀ rẹ̀, wọ́n ọkùnrin yìí ń pe Elijah.

48 Lẹ́sẹ̀kan náà, ̀kan nínú wọn sáré, ó kànìnkànìn, ó tẹ̀ ́ bọ inú ọtí kíkan. Ó fi orí ̀, ó gbé e sókè láti fi fún un mu. 49 Ṣùgbọ́n àwọn ìyókù , "fi í sílẹ̀. jẹ́ a ó bóyá Elijah yóò sọ̀kalẹ̀ láti gbà á ."

50 Nígbà Jesu kígbe ohùn rara lẹ́̀kan i, ó jọ̀wọ́ ̀rẹ̀, ó .

51 Lójúkan náà aṣọ ìkélé tẹmpili fàya, láti òkè ìsàlẹ̀. Ilẹ̀ tìtì. Àwọn àpáta sán. 52 Àwọn isà òkú ṣí sílẹ̀. ̀pọ̀ òkú àwọn ẹni mímọ́ ó ti sùn tún jíǹde. 53 Wọ́n jáde láti isà òkú lẹ́yìn àjíǹde Jesu, wọ́n lọ ìlú mímọ́. Níbẹ̀ ni wọ́n ti fi ara han ̀pọ̀ ènìyàn.

54 Nígbà balógun ̀run àti àwọn ó pẹ̀rẹ̀ wọ́n ń sọ Jesu ilẹ̀ ṣe tìtì àti ohun ó ṣẹlẹ̀, ̀wọn gidigidi, wọ́n , "Lóòótọ́ Ọmọ Ọlọ́run í ṣe!"

55 ̀pọ̀ obìnrin ó láti Galili pẹ̀Jesu láti tọ́rẹ̀ wọn ń ó láti òkèèrè. 56 Nínú àwọn obìnrin ti ó níbẹ̀ ni Maria Magdalene, àti Maria ìyá Jakọbu àti Josẹfu, àti ìyá àwọn ọmọ Sebede méjèèjì níbẹ̀ pẹ̀.

A tẹ́ Jesu sínú ibojì

57 Nígbà alẹ́ lẹ́, ọkùnrin ọlọ́rọ̀ kan láti Arimatea, à ń Josẹfu, ̀kan nínú àwọn ó jẹ́ ọmọ-ẹ̀yìn Jesu, 58 lọ sọ́dọ̀ Pilatu, ó tọrọ òkú Jesu. Pilatu pàṣẹ a gbé é fún un. 59 Josẹfu gbé òkú náà. Ó fi aṣọ funfun mímọ́ í. 60 Ó tẹ́ sínú ibojì òkúta ó gbẹ́ nínú àpáta fúnra rẹ̀. Ó òkúta ńlá ẹnu-ọ̀ibojì náà, ó lọ. 61 Maria Magdalene àti Maria kejì níbẹ̀, wọn jókòó òdìkejì ibojì náà.

Àwọn olùṣọ́ ibojì

62 Lọ́jọ́ kejì ó tẹ̀ọjọ́ ìpalẹ̀mọ́ àwọn olórí àlùfáà àti àwọn Farisi lọ sọ́dọ̀ Pilatu. 63 Wọ́n sọ fún un , "Alàgbà àwa rántí ẹlẹ́tàn n nígbà ó láyé , Lẹ́yìn ọjọ́ kẹta èmi yóò tún dìde.64 Nítorí náà, pàṣẹ a ti ibojì rẹ̀ gbọningbọnin títí ọjọ́ kẹta, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ṣe gbé lọ, wọn a bẹ̀rẹ̀ í sọ fún gbogbo ènìyàn , Òun ti jíǹde,èyí láti ṣẹlẹ̀, yóò burú fún wa púpọ̀ ju ti àkọ́kọ́ lọ."

65 Pilatu pàṣẹ , "lo àwọn olùṣọ́ yín wọn dáàbò bo ibojì náà ti fẹ́." 66 Nítorí náà wọ́n lọ. Wọ́n ṣé òkúta ibojì náà dáradára. Wọ́n fi àwọn olùṣọ́ ibẹ̀ láti dáàbò ó.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-