Publicidade

Mateus 28

Àjíǹde rẹ̀

1 kùtùkùtù òwúrọ̀ ọjọ́ kìn-ín-ní ̀sẹ̀, ilẹ̀ ti ń mọ́, Maria Magdalene àti Maria kejì lọ ibojì.

2 Wọ́n i , ìṣẹ̀lẹ̀ ńlá ṣẹ̀ ó gbogbo ilẹ̀ tìtì. Nítorí angẹli Olúwa ti sọ̀kalẹ̀ láti ̀run. Ó ti òkúta ibojì kúrò. Ó jókòó e lórí. 3 Ojú rẹ̀ tàn mọ̀nàmọ́. Aṣọ rẹ̀ jẹ́ funfun ̀gbọ̀n òwú. 4 ̀ba àwọn olùṣọ́, wọ́n wárìrì wọn dàbí òkú.

5 Nígbà náà ni angẹli náà fún àwọn obìnrin náà , "ṣe bẹ̀. Mo mọ̀ ̀yin ń Jesu a kàn mọ́ àgbélébùú. 6 Ṣùgbọ́n níhìn-ín. Nítorí ó ti jíǹde, gẹ́gẹ́ òun ti . wọlé wo ibi ti wọ́n tẹ́ . 7 Nísinsin yìí, lọ kíákíá láti sọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ , Ó ti jíǹde kúrò nínú òkú. Àti òun ń lọ Galili síwájú yín, níbẹ̀ ni ̀yin yóò gbé i,ó, o ti sọ fún yin."

8 Àwọn obìnrin náà sáré kúrò ibojì pẹ̀ìbẹ̀àti ayọ̀ ńlá. Wọ́n sáré láti sọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn nípa ìròyìn angẹli náà fi fún wọn. 9 wọ́n ti ń sáré lọ lójijì Jesu pàdé wọn. Ó , "Àlàáfíà", wọ́n wólẹ̀ níwájú rẹ̀. Wọ́n gbá a ẹsẹ̀ . Wọ́n foríbalẹ̀ fún un. 10 Nígbà náà, Jesu fún wọn , "ṣe bẹ̀. lọ sọ fún àwọn arákùnrin mi , wọ́n lọ tààrà Galili níbẹ̀ ni wọn yóò gbé mi.’ "

Àwọn olùṣọ́ ròyìn

11 àwọn obìnrin náà ti ń lọ ìlú, díẹ̀ nínú àwọn olùṣọ́ wọ́n ti ń ṣọ́ ibojì lọ sọ́dọ̀ àwọn olórí àlùfáà. 12 Wọ́n pe ìpàdé àwọn àgbàgbà Júù. Wọ́n fohùn ṣọ̀kan láti fi owó àbẹ̀tẹ́lẹ̀ fún àwọn olùṣọ́. 13 Wọ́n , "sọ fún àwọn ènìyàn , Gbogbo yín sùn nígbà àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Jesu lóru láti òkú rẹ̀.’ 14 Pilatu mọ̀ nípa rẹ̀, àwa yóò ṣe àlàyé yóò tẹ́ lọ́rùn fún un, ̀rọ̀ náà yóò fi yín." 15 Àwọn olùṣọ́ gba owó náà. Wọ́n ṣe gẹ́gẹ́ wọ́n ti darí wọn. Ìtàn yìí tàn kíákíá láàrín àwọn Júù. Wọ́n gba ìtàn náà gbọ́ títí di òní yìí.

Jesu pín iṣẹ́ ńlá fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀

16 Nígbà náà ni àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mọ́kànlá náà lọ Galili orí òkè níbi Jesu sọ wọn yóò ti òun. 17 Nígbà wọ́n i, wọ́n foríbalẹ̀ fún un. Ṣùgbọ́n díẹ̀ nínú wọn ṣe iyèméjì bóyá Jesu ni tàbí òun kọ́. 18 Nígbà náà ni Jesu fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ , "Gbogbo agbára ni ̀run àti ayé ni a ti fi fún mi. 19 Nítorí náà, lọ, sọ wọ́n di ọmọ-ẹ̀yìn orílẹ̀-èdè gbogbo, máa bamitiisi wọn orúkọ Baba àti ti Ọmọ àti ti ̀Mímọ́. 20 kọ́ wọn láti máa kíyèsi ohun gbogbo èyí mo ti pàṣẹ fún yín. Nítorí èmi pẹ̀yín ìgbà gbogbo títí ó fi òpin ayé."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-