Publicidade

Mateus 4

Ìdánwò Jesu

1 Nígbà náà ni ̀Mímọ́ darí Jesu ijù láti dán an láti ọwọ́ èṣù. 2 Lẹ́yìn Òun ti gbààwẹ̀ ogójì ̀sán àti ogójì òru, ebi ń pa á. 3 Nígbà náà ni olùdánwò tọ̀ ́ , ó , "ìwọ ṣe Ọmọ Ọlọ́run, pàṣẹ òkúta wọ̀nyí di àkàrà."

4 Ṣùgbọ́n Jesu dáhùn , "A ti kọ ìwé rẹ̀ : Ènìyàn yóò láààyè nípa àkàrà nìkan, ṣe nípa gbogbo ̀rọ̀ ti ó ti ẹnu Ọlọ́run jáde .’ "

5 Lẹ́yìn èyí ni èṣù gbé e lọ ìlú mímọ́ náà; ó gbé e ibi ṣóńṣó tẹmpili. 6 Ó , "ìwọ̀ jẹ́ Ọmọ Ọlọ́run, bẹ́ sílẹ̀ fún ara rẹ. A à ti kọ̀rẹ̀ ,

" Yóò pàṣẹ fún àwọn angẹli rẹ̀ nítorí tìrẹ

wọn yóò gbé sókè ni ọwọ́ wọn

ìwọ ó ba à fi ẹsẹ̀ rẹ gbún òkúta.’ "

7 Jesu dalóhùn, "A à ti kọ ́ , Ìwọ gbọdọ̀ dán Olúwa Ọlọ́run rẹ .’ "

8 Lẹ́̀kan i, èṣù gbé e lọ sórí òkè gíga, ó fi gbogbo ilẹ̀ ọba ayé àti gbogbo ògo wọn hàn án. 9 Ó fún un , "Gbogbo nǹkan wọ̀nyí ni èmi yóò fi fún , ìwọ foríbalẹ̀ o sìn mi."

10 Jesu fún un , "Padà kúrò lẹ́yìn mi, Satani! Nítorí a ti kọ ́ , Olúwa Ọlọ́run rẹ ni ìwọ ó fi orí balẹ̀ fún, òun nìkan ṣoṣo ni ìwọ máa sìn.’ "

11 Nígbà náà ni èṣù fi í sílẹ̀ lọ, àwọn angẹli tọ̀ ́ , wọ́n ṣe ìránṣẹ́ fún un.

Jesu bẹ̀rẹ̀ wàásù

12 Nígbà Jesu gbọ́ a ti fi Johanu sínú túbú ó padà Galili. 13 Ó kúrò Nasareti, ó lọ í gbé Kapernaumu, èyí ó létí Òkun Sebuluni àti Naftali. 14 èyí a ti sọtẹ́lẹ̀ láti ẹnu wòlíì Isaiah ṣẹ ,

15 "Ìwọ Sebuluni àti ilẹ̀ Naftali

̀lọ Òkun, ̀Jordani,

Galili ti àwọn kèfèrí.

16 Àwọn ènìyàn ń gbé ni òkùnkùn

ri ìmọ́lẹ̀ ńlá,

àti àwọn ń gbé nínú ilẹ̀ òjijì ikú

ni ìmọ́lẹ̀ tan fún."

17 Láti ìgbà náà lọ ni Jesu ti bẹ̀rẹ̀ wàásù: "ronúpìwàdà, nítorí ìjọba ̀run dẹ̀dẹ̀."

Pípe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn àkọ́kọ́

18 Jesu ti ń rìn létí Òkun Galili, ó àwọn arákùnrin méjì, Simoni, ti à ń Peteru, àti Anderu arákùnrin rẹ̀. Wọ́n ń sọ àwọ̀n wọn sínú Òkun nítorí apẹja ni wọ́n. 19 Jesu fún wọn , ", máa tọ̀ lẹ́yìn èmi yóò sọ yín di apẹja ènìyàn." 20 Lójúkan náà, wọ́n fi àwọ̀n wọn sílẹ̀, wọ́n tọ̀ ́ lẹ́yìn.

21 ó ti kúrò ibẹ̀, ò àwọn arákùnrin méjì mìíràn, Jakọbu ọmọ Sebede àti Johanu, arákùnrin rẹ̀. Wọ́n nínú ọkọ̀ ojú omi pẹ̀Sebede baba wọn, wọ́n ń di àwọ̀n wọn, Jesu àwọn náà pẹ̀. 22 Lójúkan náà, wọ́n fi ọkọ̀ ojú omi àti baba wọn sílẹ̀, wọ́n tọ̀ ́ lẹ́yìn.

Jesu ṣe ìwòsàn

23 Jesu rin káàkiri gbogbo Galili, ó ń kọ́ni Sinagọgu, ó ń wàásù ìyìnrere ti ìjọba ̀run, ó ń ṣe ìwòsàn ààrùn gbogbo àti àìsàn láàrín gbogbo ènìyàn. 24 Òkìkí rẹ̀ kàn gbogbo Siria ; wọ́n gbé àwọn aláìsàn ó onírúurú ààrùn, àwọn ó ìnira ̀èṣù, àti àwọn ti o wárápá àti àwọn ó ̀gbà; ó wọ́n sàn. 25 ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn láti Galili, Dekapoli, Jerusalẹmu, Judea, àti láti òkè odò Jordani tọ̀ ́ lẹ́yìn.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-