Publicidade

Mateus 7

Ṣíṣe ìdájọ́ ẹnìkejì

1 "ṣe ni lẹ́jọ́, a yín lẹ́jọ́. 2 Nítorí irú ìdájọ́ ̀yin ṣe, òun ni a ó ṣe fún yín; irú òsùwọ̀n ̀yin fi wọ́n, òun ni a ó fi wọ́n fún yín.

3 "Èétiṣe ìwọ fi ń wo ̀rún igi ń bẹ ojú arákùnrin rẹ, ṣùgbọ́n ìwọ kíyèsi ìtì igi ń bẹ ojú ara rẹ? 4 Tàbí ìwọ ó ti ṣe fún arákùnrin rẹ , Jẹ́ èmi yọ ̀rún igi ń bẹ ni ojú rẹ,ó ìtì igi ń bẹ ojú ìwọ tìkára rẹ. 5 Ìwọ àgàbàgebè, tètè kọ́ yọ ìtì igi jáde kúrò ojú ara rẹ , nígbà náà ni ìwọ yóò ríran kedere láti yọ ̀rún igi ń bẹ ojú arákùnrin rẹ kúrò.

6 "ṣe fi ohun mímọ́ fún ajá jẹ, ṣe sọ ohun ̀ṣọ́ olówó iyebíye yín fún ẹlẹ́dẹ̀, ̀yin ṣe bẹ́̀ wọ́n fi ẹsẹ̀ tẹ̀ wọ́n mọ́lẹ̀, wọn a padà yín, wọn a yín jẹ.

Béèrè, kànkùn, kiri

7 "Béèrè, a ó fi fún yín; kiri, ̀yin yóò ; kànkùn, a ó ṣí i sílẹ̀ fún yín. 8 Nítorí ẹnikẹ́ni ó béèrè ń gbà, ẹni ó kiri ń , ẹni kànkùn ni a yóò ṣi sílẹ̀ fún.

9 "Ta ni ọkùnrin náà ń bẹ nínú yín, ọmọ rẹ̀ béèrè àkàrà, yóò jẹ́ fi òkúta fún un? 10 Tàbí ó béèrè ẹja, yóò jẹ́ fún un ejò? 11 Ǹjẹ́ ̀yin í ṣe ènìyàn búburú mọ̀ a ti í fi ̀bùn rere fún àwọn ọmọ yín, mélòó mélòó ni Baba yín ń bẹ ̀run yóò fi ohun rere fún àwọn ó béèrè lọ́wọ́ rẹ̀? 12 Nítorí náà, nínú gbogbo ohunkóhun ti ̀yin ń fẹ́ ènìyàn ó ṣe yín, bẹ́̀ ni ̀yin ó ṣe wọn gẹ́gẹ́; nítorí èyí ni òfin àti àwọn wòlíì.

̀tóóró àti ọnà gbòòrò

13 "ba ẹnu-ọ̀tóóró wọlé; gbòòrò ni ẹnu-ọ̀náà, àti oníbùú ni ojú ̀náà ó lọ ibi ìparun, ̀pọ̀lọpọ̀ ni àwọn ẹni ń ibẹ̀ wọlé. 14 Nítorí kékeré ni ẹnu-ọ̀náà, tóóró ni ojú ̀náà, ti ó lọ ibi ìyè, díẹ̀ ni àwọn ẹni ó ń rìn ín.

Igi àti èso rẹ̀

15 "máa ṣọ́ra fún àwọn èké wòlíì wọ́n ń tọ̀ yín àwọ̀ àgùntàn, ṣùgbọ́n inú wọn apanijẹ ìkookò ni wọ́n. 16 Nípa èso wọn ni ̀yin ó fi mọ̀ wọn. Ǹjẹ́ ènìyàn ha èso àjàrà lára igi ̀gàn tàbí èso ̀pọ̀tọ́ lára ̀gún òṣùṣú? 17 Bẹ́̀ ni gbogbo igi rere a máa so èso rere ṣùgbọ́n igi búburú a máa so èso búburú. 18 Igi rere le so èso búburú, bẹ́̀ ni igi búburú so èso rere. 19 Gbogbo igi so èso rere, a e lulẹ̀, à wọ́ sínú iná. 20 Nítorí náà, nípa èso wọn ni ̀yin yóò mọ̀ wọn.

21 "í ṣe gbogbo ẹni ń , Olúwa, Olúwa,ni yóò wọ ìjọba ̀run, ṣe ẹni ń ṣe ìfẹ́ baba mi ń bẹ ̀run. 22 ̀pọ̀ ni yóò fún mi ọjọ́ náà , Olúwa, Olúwa, àwa ha sọtẹ́lẹ̀ orúkọ rẹ, àti orúkọ rẹ kọ́ ni a fi ̀pọ̀ ̀èṣù jáde, a ṣe ̀pọ̀ iṣẹ́ ìyanu? 23 Nígbà náà ni èmi yóò fún wọn , Èmi mọ̀ yín , kúrò lọ́dọ̀ mi ̀yin oníṣẹ́ ̀ṣẹ̀.’

Ọlọ́gbọ́n àti òmùgọ̀ ̀mọ̀

24 "Nítorí ẹnikẹ́ni ó gbọ́ ̀rọ̀ tèmi wọ̀nyí, ó ṣe wọn, èmi ó fiwé ọlọ́gbọ́n ènìyàn kan, ti ó kọ́ ilé rẹ̀ orí àpáta. 25 Òjò rọ̀, ìkún omi , afẹ́fẹ́ fẹ́, wọ́n lu ilé náà; síbẹ̀síbẹ̀ náà , nítorí a fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ sọlẹ̀ lórí àpáta. 26 Ẹnikẹ́ni ó gbọ́ ̀rọ̀ tèmi wọ̀nyí, ṣe wọ́n, òun ni èmi yóò fiwé aṣiwèrè ènìyàn kan ó kọ́ ilé rẹ̀ orí iyanrìn. 27 Òjò rọ̀, ìkún omi , afẹ́fẹ́ fẹ́, wọ́n lu ilé náà, ilé náà ; wíwó rẹ̀ pọ̀ jọjọ."

28 Nígbà Jesu parí sísọ nǹkan wọ̀nyí, ẹnu ya àwọn ̀pọ̀ ènìyàn ̀kọ́ rẹ̀, 29 nítorí ó ń kọ́ wọn ẹni ó àṣẹ, í ṣe i ti olùkọ́ òfin wọn.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-