Publicidade

Romanos 1

1 Paulu, ìránṣẹ́ Jesu Kristi, ẹni a ti láti jẹ́ aposteli, a ti sọ́tọ̀ láti wàásù ìyìnrere Ọlọ́run, 2 ìyìnrere ó ti ṣe ìlérí tẹ́lẹ̀ láti ẹnu àwọn wòlíì rẹ̀ nínú Ìwé Mímọ́. 3 ti Ọmọ rẹ̀, ẹni a láti inú irú-ọmọ Dafidi nípa ti ara, 4 ẹni a pinnu rẹ̀ láti jẹ́ Ọmọ Ọlọ́run nínú agbára gẹ́gẹ́ ̀ìwà mímọ́, nípa àjíǹde kúrò nínú òkú, àní Jesu Kristi Olúwa wa. 5 Láti ̀dọ̀ ẹni àwa oore-ọ̀fẹ́ àti jíjẹ́ aposteli gbà, fún ìgbọ́ràn ìgbàgbọ́ láàrín gbogbo orílẹ̀-èdè, nítorí orúkọ rẹ̀. 6 ̀yin pẹ̀si wa lára àwọn a sọ́dọ̀ Jesu Kristi.

7 gbogbo àwọn àyànfẹ́ Ọlọ́run ó Romu a ti láti jẹ́ ènìyàn mímọ́:

Oore-ọ̀fẹ́ àti àlàáfíà fún yín láti ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba wa àti láti ̀dọ̀ Olúwa wa Jesu Kristi.

Ìfojúsọ́Paulu láti bẹ Romu

8 àkọ́kọ́, mo dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run nípasẹ̀ Jesu Kristi fún gbogbo yín, nítorí a ń ròyìn ìgbàgbọ́ yin káàkiri gbogbo ayé. 9 Ọlọ́run ṣá à ni ẹlẹ́rìí mi, ẹni èmí ń fi gbogbo ̀mi sìn nínú ìyìnrere Ọmọ rẹ̀, ó ti ṣe àìsimi ni èmí ń rántí yín nígbà gbogbo nínú àdúrà mi 10 nínú àdúrà mi ìgbà gbogbo; mo tún ń gbàdúrà nípa oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run ̀ó ṣí fún mi láti sọ́dọ̀ yín.

11 Nítorí èmi ń fẹ́ gidigidi láti tọ̀ yín , èmi fún yín ̀bùn ̀díẹ̀, a a le sọ yín di alágbára nínú Olúwa, 12 èyí ni , a jẹ́ ìwúrí fún ara wa nípa ìgbàgbọ́ ẹnìkọ̀̀kan wa. 13 Mo fẹ́ mọ èyí, ̀yin ará mi, mo ti gbìyànjú lọ́pọ̀ ìgbà láti tọ̀ yín (ṣùgbọ́n ìdíwọ́ fún mi), èmi ki ó jèrè ọkàn díẹ̀ láàrín yín, gẹ́gẹ́ mo ti láàrín àwọn aláìkọlà yòókù.

14 Nítorí mo jẹ́ ajigbèsè Giriki àti àwọn aláìgbédè í ṣe Giriki, àwọn ọlọ́gbọ́n àti àwọn aṣiwèrè. 15 Nítorí ìdí èyí ni mo ṣe ń làkàkà láti Romu àti láti fi gbogbo agbára mi wàásù ìyìnrere Ọlọ́run i yín.

16 Èmi tijú ìyìnrere Jesu, nítorí agbára Ọlọ́run ín ṣe láti gba gbogbo àwọn ó gbàgbọ́ , ̀rọ̀ yìí ni a kọ́kọ́ wàásù àwọn Júù nìkan, ṣùgbọ́n nísinsin yìí fún àwọn Helleni pẹ̀. 17 Nítorí nínú ìyìnrere ni òdodo Ọlọ́run ti farahàn, òdodo Ọlọ́run nípa ìgbàgbọ́ láti ìbẹ̀rẹ̀ òpin gẹ́gẹ́ a ti kọ ́ nínú Ìwé Mímọ́ , "Olódodo yóò nípa ìgbàgbọ́ rẹ̀."

Ìbínú Ọlọ́run orílẹ̀ ayé

18 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run fi ìbínú rẹ̀ hàn láti ̀run gbogbo àìwà-bí-Ọlọ́run àti gbogbo àìṣòdodo ènìyàn, àwọn ń fi ìwà búburú dènà ìmọ̀ òtítọ́ lọ́dọ̀ ènìyàn. 19 Nítorí , nǹkan gbogbo a mọ nípa Ọlọ́run ni a ti fihàn fún wọn, nítorí Ọlọ́run ti fi í hàn fún wọn. 20 Nítorí láti ìgbà dídá ayé, gbogbo ohun àìlèfojúrí rẹ̀, agbára ayérayé àti ìwà-bí-Ọlọ́run rẹ̀ ni a gbangba a ń fi òye ohun a mọ̀ ́n ènìyàn ba à àwáwí.

21 Lóòótọ́, wọn òye nípa Ọlọ́run dáradára, ṣùgbọ́n wọn yìn ín lógo Ọlọ́run, wọ́n dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ̀; wọ́n ń ro èrò asán, ọkàn aṣiwèrè wọn ṣókùnkùn. 22 Níwọ́n ó tilẹ̀ jẹ́ wọ́n pe ara wọn ọlọ́gbọ́n ṣùgbọ́n wọ́n di òmùgọ̀ pátápátá, 23 wọ́n ògo Ọlọ́run í díbàjẹ́ àwọn àwòrán ère i ti ènìyàn í díbàjẹ́ àti ti ẹyẹ, àti ti ẹranko ẹlẹ́sẹ̀ mẹ́rin àti ti ẹranko afàyàfà.

24 Nítorí náà Ọlọ́run wọ́n ìfẹ́kúfẹ̀́ ọkàn wọn lọ́wọ́ láti máa ṣe ohun ìríra pẹ̀ara wọn èyí tọ́. 25 Wọ́n òtítọ́ Ọlọ́run èké, wọ́n ń foríbalẹ̀ láti máa sin ̀dípò ẹlẹ́dàáẹni ìyìn tọ́ láéláé. Àmín.

26 Nítorí èyí yìí ni Ọlọ́run ṣe fi wọ́n fún ìfẹ́kúfẹ̀́, nítorí àwọn obìnrin wọn tilẹ̀ ń ìṣẹ̀ìbáṣepọ̀ ó tọ̀, èyí tọ̀. 27 Gẹ́gẹ́ bẹ́̀ ni àwọn ọkùnrin pẹ̀, wọn a máa fi ìbálòpọ̀ obìnrin nípa ti ̀sílẹ̀, wọn a máa fẹ́ ìfẹ́kúfẹ̀́ ara wọn, ọkùnrin ń ọkùnrin ṣe èyí yẹ, wọ́n ǹ jẹ èrè ìṣìnà wọn nínú ara wọn ó ti yẹ .

28 Àti gẹ́gẹ́ wọ́n ti kọ̀ láti gba Ọlọ́run nínú ìmọ̀ ó tọ́, Ọlọ́run fi wọ́n fún iyè ríra láti ṣe ohun tọ́ fún wọn láti ṣe. 29 Wọ́n kún fún onírúurú àìṣòdodo gbogbo, àgbèrè, ìkà, ojúkòkòrò, àrankàn; wọ́n kún fún ìlara, ìpànìyàn, ìjà, ìtànjẹ, ìwà búburú; wọ́n jẹ́ afọ̀rọ̀kẹ́lẹ́ ba ni jẹ́. 30 Asọ̀rọ̀ ẹni lẹ́yìn, akórìíra Ọlọ́run, aláfojúdi, agbéraga, ahalẹ̀, aláròṣe ohun búburú, aṣàìgbọràn òbí, 31 aláìníyè nínú, ̀dàlẹ̀, aláìnígbàgbọ́, ̀dájú, aláìláàánú. 32 ó tilẹ̀ jẹ́ wọ́n mọ ìlànà Ọlọ́run , ẹni ó ṣe irú nǹkan wọ̀nyí yẹ ikú, wọn inú dídùn àwọn nǹkan wọ̀nyí nìkan ṣùgbọ́n wọ́n inú dídùn àwọn ń ṣe wọ́n.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-