Publicidade

Romanos 12

Ẹbọ ààyè mímọ́

1 12.1: Ro 6.13,16,19; 1Pt 2.5. Nítorí náà mo fi ìyọ́Ọlọ́run bẹ̀ yín ará, ̀yin ó fi ara yín fún Ọlọ́run ẹbọ ààyè mímọ́, ìtẹ́wọ́gbà, èyí ni iṣẹ́ ìsìn yín ó tọ̀. 2 12.2: 1Jh 2.15; Ef 4.23; 5.10.da ara yín pọ̀ mọ́ ayé yìí; ṣùgbọ́n paradà láti di tuntun èrò inú yín, ̀yin ó ìdí ìfẹ́ Ọlọ́run, ó dára, ó ṣe ìtẹ́wọ́gbà, ti ó .

Ìsìn ìrẹ̀lẹ̀ nínú Kristi

3 Ǹjẹ́ mo fún olúkúlùkù ènìyàn ó nínú yín, nípa oore-ọ̀fẹ́ a fi fún mi, ó ṣe ro ara rẹ̀ ju ó ti yẹ rírò lọ; ṣùgbọ́n ó le níwọ́ntúnwọ́nsì, Ọlọ́run ti fi ìwọ̀n ìgbàgbọ́ fún olúkúlùkù. 4 12.4: 1Kọ 12.12-14; Ef 4.4,16.Nítorí gẹ́gẹ́ àwa ti ̀púpọ̀ nínú ara kan, gbogbo ̀iṣẹ́ kan náà, 5 12.5: 1Kọ 10.17; 12.20,27; Ef 4.25.bẹ́̀ ni àwa, a jẹ́ púpọ̀, a jẹ́ ara kan nínú Kristi, àti olúkúlùkù ̀ara ọmọnìkejì rẹ̀. 6 12.6-8: 1Kọ 7.7; 12.4-11; 1Pt 4.10-11.Ǹjẹ́ àwa ti ń ̀tọ̀̀tọ̀ ̀bùn gbà gẹ́gẹ́ oore-ọ̀fẹ́ a fi fún wa, ó ṣe ìsọtẹ́lẹ̀ ni, a máa sọtẹ́lẹ̀ gẹ́gẹ́ ìwọ̀n ìgbàgbọ́; 7 tàbí iṣẹ́ ìránṣẹ́, a kọjú iṣẹ́ ìránṣẹ́ wa tàbí ẹni ń kọ́ni, ó kọjú kíkọ́. 8 Tàbí ẹni ó ń gbani níyànjú, ìgbìyànjú; ẹni ń fi fún ni ó máa fi inú kan ṣe é; ẹni ń ṣe olórí, ó máa ṣe é ojú méjèèjì; ẹni ń ṣàánú, ó máa fi inú dídùn ṣe é.

̀kọ́ nípa ìfẹ́

9 ìfẹ́ ó àìṣẹ̀tàn. máa takété ohun í ṣe búburú; fi ara mọ́ ohun í ṣe rere. 10 ti ìfẹ́ ará, máa fi ìyọ́fẹ́ràn ara yín; ti ọlá, máa fi ẹnìkejì yín ṣáájú. 11 ti iṣẹ́ ṣíṣe, ṣe ̀lẹ; máa ìgbóná ọkàn; máa sìn Olúwa. 12 12.12: Ap 1.14; Ro 5.2; 1Tẹ 5.17.máa yọ̀ ni ìrètí; máa sùúrù nínú ìpọ́njú; máa dúró gbọingbọin nínú àdúrà. 13 máa pèsè fún àìní àwọn ènìyàn mímọ́; fi ara yín fún àlejò ṣíṣe.

14 12.14: Mt 5.44; Lk 6.28. máa súre fún àwọn ń ṣe inúnibíni yín; máa súre, ṣépè. 15 Àwọn ń yọ̀, máa wọn yọ̀, àwọn ń sọkún, máa wọn sọkún. 16 12.16: Ro 11.25; 15.5; 1Kọ 1.10; 2Kọ 13.11; Fp 2.2; 4.2; Òw 3.7; 26.12.máa inú kan náà ara yín. ṣe gbéraga, ṣùgbọ́n tẹ̀àwọn onírẹ̀lẹ̀. ṣe jẹ́ ọlọ́gbọ́n ojú ara yín.

17 12.17: Òw 20.22; 2Kọ 8.21; 1Tẹ 5.15. ṣe fi búburú san búburú fún ẹnikẹ́ni. pèsè ohun ó tọ́ níwájú gbogbo ènìyàn. 18 12.18: Mk 9.50; Ro 14.19.ó é ṣe, ó ti ipa tiyín, àlàáfíà pẹ̀gbogbo ènìyàn. 19 12.19: Le 19.18; De 32.35; Hb 10.30.Olùfẹ́ mi ̀wọ́n, ṣe gbẹ̀san ara yín, ṣùgbọ́n fi ààyè sílẹ̀ fún ìbínú Ọlọ́run; nítorí a ti kọ ́ , Olúwa , "Tèmi ni ̀san, èmi ó gbẹ̀san." 20 12.20: Òw 25.21-22; Mt 5.44; Lk 6.27.òdìkejì ̀wẹ̀,

"ebi ń pa ̀rẹ, fún un oúnjẹ;

òùngbẹ ń gbẹ ́, fún un omi mu.

ṣíṣe èyí, ìwọ ó ̀yín iná e orí."

21 ṣe jẹ́ búburú ṣẹ́gun rẹ, ṣùgbọ́n fi rere ṣẹ́gun búburú.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-