Publicidade

Romanos 14

10 14.10: 2Kọ 5.10. Èéṣe nígbà náà ìwọ fi ń arákùnrin tàbí arábìnrin rẹ lẹ́jọ́? Tàbí èéṣe ìwọ fi ń gàn wọn? Nítorí gbogbo wa ni yóò dúró níwájú ìtẹ́ ìdájọ́ Ọlọ́run. 11 14.11: Isa 45.23; Fp 2.10-11.A ti kọ ìwé rẹ̀ :

" Níwọ́n ìgbà mo láààyè,ni Olúwa ,

gbogbo eékún ni yóò wólẹ̀ fún mi;

gbogbo ahọ́n ni yóò jẹ́wọ́ fún Ọlọ́run.’ "

12 Ǹjẹ́ nítorí náà, olúkúlùkù wa ni yóò jíyìn ara rẹ̀ fún Ọlọ́run.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-