Publicidade

Romanos 15

1 Àwa a jẹ́ alágbára nínú ìgbàgbọ́ yẹ ó máa ru ẹrù àìlera àwọn aláìlera, a ṣe ohun ó wu ara wa. 2 Olúkúlùkù wa gbọdọ̀ máa ṣe ohun ó wu ọmọnìkejì rẹ̀ rere, láti gbé e . 3 15.3: Sm 69.9.Nítorí Kristi pàápàá ṣe ohun ó wu ara rẹ̀, ṣùgbọ́n a ti kọ ́ , "̀gàn àwọn ẹni ń gàn ́ ṣubú mi." 4 15.4: Ro 4.23-24; 1Kọ 9.10; 2Tm 3.16.Nítorí ohun gbogbo a kọ tẹ́lẹ̀, ni a kọ láti fi kọ́ wa , nípa sùúrù àti ìtùnú ìwé mímọ́, àwa ìrètí.

5 15.5: Ro 12.16; 1Kọ 1.10; 2Kọ 13.11; Fp 2.2; 4.2. Ọlọ́run, ẹni ń fún ni sùúrù àti ìtùnú fún yin láti inú kan ara yín gẹ́gẹ́ i Jesu Kristi, 6 ̀yin ó fi ọkàn kan àti ẹnu kan fi ògo fún Ọlọ́run, Baba Olúwa wa Jesu Kristi.

7 Nítorí náà gba ara yín mọ́ra, gẹ́gẹ́ Kristi ti gbà mọ́ra fún ògo Ọlọ́run. 8 Mo , a rán Kristi láti ṣe ìránṣẹ́ ìkọlà àwọn ṣe Júù nítorí òtítọ́ Ọlọ́run, láti fi ìdí àwọn ìlérí a ti ṣe fún àwọn baba múlẹ̀, 9 15.9: Sm 18.49; 2Sa 22.50.àwọn aláìkọlà ó yin Ọlọ́run lógo nítorí àánú rẹ̀; gẹ́gẹ́ a ti kọ ́ :

"Nítorí èyí ni èmi ó ṣe yìn ́ láàrín àwọn Kèfèrí,

Èmi ó kọrin orúkọ rẹ."

10 15.10: De 32.43. Ó tún ,

"̀yin Kèfèrí, ma yọ̀, pẹ̀àwọn ènìyàn rẹ̀."

11 15.11: Sm 117.1. Àti pẹ̀,

"Ẹyin Olúwa, gbogbo ̀yin Kèfèrí;

kọ orin ìyìn , ̀yin ènìyàn gbogbo."

12 15.12: Isa 11.10; Mt 12.21. Isaiah tún ,

"Gbòǹgbò Jese kan ń bọ̀ ,

òun ni ẹni yóò dìde ṣe àkóso àwọn Kèfèrí;

Àwọn Kèfèrí yóò ìrètí nínú rẹ̀."

13 Ǹjẹ́ Ọlọ́run ìrètí ó fi gbogbo ayọ̀ òun àlàáfíà kún yín ̀yin ti gbà á gbọ́, ̀yin ó pọ̀ ìrètí nípa agbára ̀Mímọ́.

Paulu wàásù àwọn Kèfèrí

14 ̀yin ará, èmi gan alára ti ìdánilójú, ̀yin pàápàá kún fún oore, a fi gbogbo ìmọ̀ kún un yín, ̀yin jáfáfá láti máa kọ́ ara yín. 15 Síbẹ̀ mo ti fi ìgboyà kọ̀yín lórí àwọn kókó-ọ̀rọ̀ kan, ẹni ti ń rán yín létí àwọn kókó-ọ̀rọ̀ náà, nítorí oore-ọ̀fẹ́ a ti fi fún mi láti ̀dọ̀ Ọlọ́run 16 15.16: Ap 9.15.láti jẹ́ ìránṣẹ́ Kristi Jesu láàrín àwọn Kèfèrí láti polongo ìyìnrere Ọlọ́run gẹ́gẹ́ ojúṣe àlùfáà, àwọn Kèfèrí jẹ́ ẹbọ ọrẹ ìtẹ́wọ́gbà fún Ọlọ́run, èyí a ti fi ̀Mímọ́ mímọ́.

17 Nítorí náà, mo ìṣògo nínú Kristi Jesu nínú iṣẹ́ ìránṣẹ́ mi fún Ọlọ́run. 18 15.18: Ro 1.5; Ap 15.12; 21.19.Èmi à gbọdọ̀ sọ ohun kan ṣe èyí Kristi ti ọwọ́ mi ṣe, títọ́ àwọn Kèfèrí ṣọ́láti ṣe ìgbọ́ràn ̀rọ̀ Ọlọ́run nípa ̀rọ̀ àti ìṣe mi, 19 15.19: Ap 19.11; 2Kọ 12.12.nípa agbára iṣẹ́ àmì àti iṣẹ́ ìyanu, nípa agbára ̀Ọlọ́run, bẹ́̀ láti Jerusalẹmu àti yíkákiri, àní títí fi Illirikoni, mo ti polongo ìyìnrere Kristi ̀kúnrẹ́rẹ́. 20 15.20: 2Kọ 10.15-16.Ó jẹ́ èrò mi gbogbo ìgbà láti wàásù ìyìnrere Kristi ibi gbogbo wọn ì mọ̀ ́n, èmi ó ṣe máa mọ àmọlé lórí ìpìlẹ̀ ẹlòmíràn. 21 15.21: Isa 52.15.Ṣùgbọ́n, gẹ́gẹ́ a ti kọ ́ :

"Àwọn ẹni a ì sọ ̀rọ̀ rẹ̀ fún yóò i,

àti àwọn ì gbọ́, òye yóò ."

22 15.22: Ro 1.13. Ìdí nìyìí ààyè fi pẹ́ bẹ́̀ fún mi n tọ̀ yín wa.

Paulu ṣètò láti ṣé àbẹ̀Romu

23 15.23: Ap 19.21; Ro 1.10-11; 15.32. Ṣùgbọ́n báyìí tún ibòmíràn fún mi mọ́ láti ṣiṣẹ́ ẹkùn yìí, èmi ti ń pòǹgbẹ láti ọdún púpọ̀ sẹ́yìn láti bẹ́ yín , 24 15.24: Ro 15.28.mo gbèrò láti ṣe bẹ́̀ nígbà mo lọ Spania. Èmi yóò i yín ̀àjò mi, àti ó mi ̀níbẹ̀ láti ̀dọ̀ yín lọ, lẹ́yìn mo gbádùn ẹgbẹ́ yín fún ìgbà díẹ̀. 25 15.25: Ap 19.21; 24.17; 15.31.Ṣùgbọ́n báyìí, mo ń lọ Jerusalẹmu láti ìránṣẹ́ fún àwọn ènìyàn mímọ́ níbẹ̀. 26 15.26: 2Kọ 8.1-5; 9.2; 1Tẹ 1.7-8.Nítorí ó wu àwọn ó Makedonia àti Akaia láti owó jọ fún àwọn tálákà ó àárín àwọn ènìyàn mímọ́ Jerusalẹmu. 27 15.27: 1Kọ 9.11.Pẹ̀ayọ̀ ni wọ́n ń ṣe èyí, nítorí wọ́n gbà , wọ́n jẹ́ ajigbèsè fún wọn. Nítorí ó ṣe a fi àwọn Kèfèrí ṣe alájọni nínú ohun ̀wọn, ajigbèsè ni wọn láti fi ohun ti ara ta wọ́n lọ́rẹ. 28 15.28: Ro 15.24.Nítorí náà, nígbà mo ti ṣe èyí tán, mo di èdìdì èso náà fún wọn tán, èmi yóò ti ̀dọ̀ yín lọ Spania. 29 15.29: Ap 19.21.Mo mọ̀ nígbà mo ̀dọ̀ yín, èmi yóò ̀kúnrẹ́rẹ́ ìbùkún ìyìnrere Kristi.

30 Èmí rọ̀ yín, ̀yin arákùnrin àti arábìnrin, nítorí Olúwa wa Jesu Kristi, àti nítorí ìfẹ́ ̀, ̀yin ó kún mi láti mi làkàkà nínú àdúrà yín Ọlọ́run fún mi. 31 15.31: 2Tẹ 3.2; Ro 15.25-26; 2Kọ 8.4; 9.1.a mi yọ kúrò lọ́wọ́ àwọn aláìgbàgbọ́ Judea àti iṣẹ́ ìránṣẹ́ mo Jerusalẹmu le jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà lọ́dọ̀ àwọn ènìyàn mímọ́ níbẹ̀, 32 15.32: Ro 1.10; Ap 19.21.èmi le fi ayọ̀ tọ̀ yín wa, nípa ìfẹ́ Ọlọ́run, àti èmi ìtura pọ̀ pẹ̀yín. 33 15.33: 2Kọ 13.11; Fp 4.9.Ọlọ́run àlàáfíà pẹ̀gbogbo yín. Àmín.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-