Publicidade

Romanos 15

1 Àwa a jẹ́ alágbára nínú ìgbàgbọ́ yẹ ó máa ru ẹrù àìlera àwọn aláìlera, a ṣe ohun ó wu ara wa. 2 Olúkúlùkù wa gbọdọ̀ máa ṣe ohun ó wu ọmọnìkejì rẹ̀ rere, láti gbé e . 3 Nítorí Kristi pàápàá ṣe ohun ó wu ara rẹ̀, ṣùgbọ́n a ti kọ ́ , "̀gàn àwọn ẹni ń gàn ́ ṣubú mi." 4 Nítorí ohun gbogbo a kọ tẹ́lẹ̀, ni a kọ láti fi kọ́ wa , nípa sùúrù àti ìtùnú ìwé mímọ́, àwa ìrètí.

5 Ọlọ́run, ẹni ń fún ni sùúrù àti ìtùnú fún yin láti inú kan ara yín gẹ́gẹ́ i Jesu Kristi, 6 ̀yin ó fi ọkàn kan àti ẹnu kan fi ògo fún Ọlọ́run, Baba Olúwa wa Jesu Kristi.

7 Nítorí náà gba ara yín mọ́ra, gẹ́gẹ́ Kristi ti gbà mọ́ra fún ògo Ọlọ́run. 8 Mo , a rán Kristi láti ṣe ìránṣẹ́ ìkọlà àwọn ṣe Júù nítorí òtítọ́ Ọlọ́run, láti fi ìdí àwọn ìlérí a ti ṣe fún àwọn baba múlẹ̀, 9 àwọn aláìkọlà ó yin Ọlọ́run lógo nítorí àánú rẹ̀; gẹ́gẹ́ a ti kọ ́ :

"Nítorí èyí ni èmi ó ṣe yìn ́ láàrín àwọn Kèfèrí,

Èmi ó kọrin orúkọ rẹ."

10 Ó tún ,

"̀yin Kèfèrí, ma yọ̀, pẹ̀àwọn ènìyàn rẹ̀."

11 Àti pẹ̀,

"Ẹyin Olúwa, gbogbo ̀yin Kèfèrí;

kọ orin ìyìn , ̀yin ènìyàn gbogbo."

12 Isaiah tún ,

"Gbòǹgbò Jese kan ń bọ̀ ,

òun ni ẹni yóò dìde ṣe àkóso àwọn Kèfèrí;

Àwọn Kèfèrí yóò ìrètí nínú rẹ̀."

13 Ǹjẹ́ Ọlọ́run ìrètí ó fi gbogbo ayọ̀ òun àlàáfíà kún yín ̀yin ti gbà á gbọ́, ̀yin ó pọ̀ ìrètí nípa agbára ̀Mímọ́.

Paulu wàásù àwọn Kèfèrí

14 ̀yin ará, èmi gan alára ti ìdánilójú, ̀yin pàápàá kún fún oore, a fi gbogbo ìmọ̀ kún un yín, ̀yin jáfáfá láti máa kọ́ ara yín. 15 Síbẹ̀ mo ti fi ìgboyà kọ̀yín lórí àwọn kókó-ọ̀rọ̀ kan, ẹni ti ń rán yín létí àwọn kókó-ọ̀rọ̀ náà, nítorí oore-ọ̀fẹ́ a ti fi fún mi láti ̀dọ̀ Ọlọ́run 16 láti jẹ́ ìránṣẹ́ Kristi Jesu láàrín àwọn Kèfèrí láti polongo ìyìnrere Ọlọ́run gẹ́gẹ́ ojúṣe àlùfáà, àwọn Kèfèrí jẹ́ ẹbọ ọrẹ ìtẹ́wọ́gbà fún Ọlọ́run, èyí a ti fi ̀Mímọ́ mímọ́.

17 Nítorí náà, mo ìṣògo nínú Kristi Jesu nínú iṣẹ́ ìránṣẹ́ mi fún Ọlọ́run. 18 Èmi à gbọdọ̀ sọ ohun kan ṣe èyí Kristi ti ọwọ́ mi ṣe, títọ́ àwọn Kèfèrí ṣọ́láti ṣe ìgbọ́ràn ̀rọ̀ Ọlọ́run nípa ̀rọ̀ àti ìṣe mi, 19 nípa agbára iṣẹ́ àmì àti iṣẹ́ ìyanu, nípa agbára ̀Ọlọ́run, bẹ́̀ láti Jerusalẹmu àti yíkákiri, àní títí fi Illirikoni, mo ti polongo ìyìnrere Kristi ̀kúnrẹ́rẹ́. 20 Ó jẹ́ èrò mi gbogbo ìgbà láti wàásù ìyìnrere Kristi ibi gbogbo wọn ì mọ̀ ́n, èmi ó ṣe máa mọ àmọlé lórí ìpìlẹ̀ ẹlòmíràn. 21 Ṣùgbọ́n, gẹ́gẹ́ a ti kọ ́ :

"Àwọn ẹni a ì sọ ̀rọ̀ rẹ̀ fún yóò i,

àti àwọn ì gbọ́, òye yóò ."

22 Ìdí nìyìí ààyè fi pẹ́ bẹ́̀ fún mi n tọ̀ yín wa.

Paulu ṣètò láti ṣé àbẹ̀Romu

23 Ṣùgbọ́n báyìí tún ibòmíràn fún mi mọ́ láti ṣiṣẹ́ ẹkùn yìí, èmi ti ń pòǹgbẹ láti ọdún púpọ̀ sẹ́yìn láti bẹ́ yín , 24 mo gbèrò láti ṣe bẹ́̀ nígbà mo lọ Spania. Èmi yóò i yín ̀àjò mi, àti ó mi ̀níbẹ̀ láti ̀dọ̀ yín lọ, lẹ́yìn mo gbádùn ẹgbẹ́ yín fún ìgbà díẹ̀. 25 Ṣùgbọ́n báyìí, mo ń lọ Jerusalẹmu láti ìránṣẹ́ fún àwọn ènìyàn mímọ́ níbẹ̀. 26 Nítorí ó wu àwọn ó Makedonia àti Akaia láti owó jọ fún àwọn tálákà ó àárín àwọn ènìyàn mímọ́ Jerusalẹmu. 27 Pẹ̀ayọ̀ ni wọ́n ń ṣe èyí, nítorí wọ́n gbà , wọ́n jẹ́ ajigbèsè fún wọn. Nítorí ó ṣe a fi àwọn Kèfèrí ṣe alájọni nínú ohun ̀wọn, ajigbèsè ni wọn láti fi ohun ti ara ta wọ́n lọ́rẹ. 28 Nítorí náà, nígbà mo ti ṣe èyí tán, mo di èdìdì èso náà fún wọn tán, èmi yóò ti ̀dọ̀ yín lọ Spania. 29 Mo mọ̀ nígbà mo ̀dọ̀ yín, èmi yóò ̀kúnrẹ́rẹ́ ìbùkún ìyìnrere Kristi.

30 Èmí rọ̀ yín, ̀yin arákùnrin àti arábìnrin, nítorí Olúwa wa Jesu Kristi, àti nítorí ìfẹ́ ̀, ̀yin ó kún mi láti mi làkàkà nínú àdúrà yín Ọlọ́run fún mi. 31 a mi yọ kúrò lọ́wọ́ àwọn aláìgbàgbọ́ Judea àti iṣẹ́ ìránṣẹ́ mo Jerusalẹmu le jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà lọ́dọ̀ àwọn ènìyàn mímọ́ níbẹ̀, 32 èmi le fi ayọ̀ tọ̀ yín wa, nípa ìfẹ́ Ọlọ́run, àti èmi ìtura pọ̀ pẹ̀yín. 33 Ọlọ́run àlàáfíà pẹ̀gbogbo yín. Àmín.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-