Publicidade

Romanos 2

Ìdájọ́ òdodo Ọlọ́run

1 2.1: Ro 14.22. Nítorí náà, aláìríwí ni ẹnikẹ́ni ó ó jẹ́ ń ni lẹ́jọ́, nítorí nínú ohun ìwọ ń ṣe ìdájọ́ ẹlòmíràn, ìwọ ń ara rẹ lẹ́bi; nítorí ìwọ ń dájọ́ ń ṣe ohun kan náà nínú èyí ìwọ ń ni lẹ́jọ́. 2 Ṣùgbọ́n àwa mọ̀ ìdájọ́ Ọlọ́run jẹ́ òtítọ́ si gbogbo àwọn ó ń ṣe irú ohun báwọ̀nyí. 3 Nítorí ìwọ ń ṣe ènìyàn lásán ń ṣe ìdájọ́ àwọn ń ṣe irú ohun báwọ̀nyí, ìwọ tìkára rẹ ń ṣe bẹ́̀, ìwọ ro èyí ìwọ o yọ nínú ìdájọ́ Ọlọ́run ?

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-