Pular para o conteúdo
Publicidade

Romanos 2

6 2.6: Mt 16.27; 1Kọ 3.8; 2Kọ 5.10; If 22.12.Ọlọ́run yóò san án fún olúkúlùkù gẹ́gẹ́ iṣẹ́ rẹ̀. 7 Àwọn ẹni ń fi sùúrù nínú rere ṣíṣe, ògo àti ọlá àti àìdíbàjẹ́ ni yóò fi ìyè àìnípẹ̀kun fún. 8 Ṣùgbọ́n fún àwọn onímọ̀-tara-ẹni-nìkan, wọn gba òtítọ́ gbọ́, ṣùgbọ́n wọn ń tẹ̀̀búburú, wọn yóò ìrírí ìrunú àti ìbínú rẹ̀. 9 Ìpọ́njú àti ìrora, yóò lórí olúkúlùkù ọkàn ènìyàn ń hùwà ibi: ti Júù ṣáájú, àti àwọn Helleni pẹ̀; 10 ṣùgbọ́n ògo, àti ọlá, àti àlàáfíà, fún olúkúlùkù ẹni ń hùwà rere, fún Júù, ṣáájú àti fún àwọn Helleni pẹ̀. 11 Nítorí Ọlọ́run í ṣe ojúsàájú ènìyàn.

Veja também