Pular para o conteúdo
Publicidade

Romanos 3

Ìṣòtítọ́ Ọlọ́run

1 Ǹjẹ́ àǹfààní wo Júù ? Tàbí kín ni èrè ilà kíkọ? 2 3.2: Sm 147.19; Ro 9.4.Púpọ̀ lọ́gbogbo; pàtàkì jùlọ ni àwọn ni a fi ̀rọ̀ Ọlọ́run lọ́wọ́.

3 Ǹjẹ́ ha ni àwọn kan jẹ́ aláìgbàgbọ́? Àìgbàgbọ́ wọn yóò ha sọ òtítọ́ Ọlọ́run di asán ? 4 3.4: Sm 51.4.a ! Ọlọ́run jẹ́ olóòtítọ́, àti olúkúlùkù ènìyàn jẹ́ èké; gẹ́gẹ́ a ti kọ ́ :

"a láre nínú ̀rọ̀ rẹ,

ṣùgbọ́n ìwọ borí nígbà ìwọ ìdájọ́."

5 3.5: Ro 5.9; 6.19; 1Kọ 9.8; Ga 3.15. Ṣùgbọ́n àìṣòdodo wa fi òdodo Ọlọ́run hàn, kín ni àwa ó ? Ọlọ́run ha jẹ́ àìṣòdodo , nígbà ó ń fi ìbínú rẹ̀ hàn? (Mo fi ṣe àkàwé ènìyàn.) 6 a i. bẹ́̀ ni, Ọlọ́run yóò ha ṣe dájọ́ aráyé? 7 Nítorí òtítọ́ Ọlọ́run di púpọ̀ ìyìn rẹ̀ nítorí èké mi, èéṣe a fi ń mi lẹ́jọ́ ẹlẹ́ṣẹ̀? 8 3.8: Ro 6.1,15.Èéṣe a fi ṣe búburú rere jáde ? àwọn kan ń fi ẹnu àtẹ́ sọ a ń sọ bẹ́̀; ti àwọn kan ń tẹnumọ́ ọn a sọ; àwọn ẹni ìdálẹ́bi wọn tọ́.

olóòtítọ́ kan

9 3.9: Ro 1.18-32; 2.1-29; 11.32; 3.23. Ǹjẹ́ ha ni? Àwa ha sàn ju wọn lọ ? bẹ́̀ rárá, nítorí a fihàn ṣáájú àti àwọn Júù àti àwọn Giriki, gbogbo wọn ni ó lábẹ́ ̀ṣẹ̀. 10 3.10-12: Sm 14.1-3; 53.1-3.Gẹ́gẹ́ a ti kọ ́ ,

"ẹni í ṣe olódodo, ẹnìkan,

11 ẹni òye ,

ẹni ó ń Ọlọ́run.

12 Gbogbo wọn ni ó ti yapa,

wọ́n jùmọ̀ di aláìlérè;

ẹni ń ṣe rere,

tilẹ̀ ẹnìkan."

13 3.13: Sm 5.9; 140.3. "Ibojì ó ṣí sílẹ̀ ̀fun wọn:

ahọ́n wọn n sọ̀rọ̀ ̀tàn."

"Oró paramọ́lẹ̀ ń bẹ lábẹ́ ètè wọn."

14 3.14: Sm 10.7. "Ẹnu ẹni ó kún fún èpè àti fún oró kíkorò."

15 3.15-17: Isa 59.7-8. "Ẹsẹ̀ wọn yára láti ta ̀jẹ̀ sílẹ̀,

16 ìparun àti ìpọ́njú lọ́wọn.

17 ̀àlàáfíà ni wọn mọ̀,"

18 3.18: Sm 36.1. "Ìbẹ̀Ọlọ́run níwájú wọn."

19 3.19: Ro 2.12. Àwa mọ̀ ohunkóhun òfin , ó ń fún àwọn ó lábẹ́ òfin: gbogbo ẹnu à dákẹ́ àti a gbogbo aráyé sábẹ́ ìdájọ́ Ọlọ́run. 20 3.20: Sm 143.2; Ap 13.39; Ga 2.16; 3.11; Ro 7.7.Nítorí nípa iṣẹ́ òfin, a yóò ẹnikẹ́ni láre níwájú rẹ̀: nítorí nípa òfin ni ìmọ̀ ̀ṣẹ̀ ti .

Ìṣòdodo nípa ìgbàgbọ́

21 3.21: Ro 1.17; Fp 3.9; 2Pt 1.1. Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, a ti fi òdodo Ọlọ́run hàn láìsí òfin, a ti ń jẹ́rìí nípa òfin àti nípa àwọn wòlíì, 22 3.22: Ro 4.5; 9.30; 10.12; Ga 2.16.àní òdodo Ọlọ́run nípa ìgbàgbọ́ nínú Jesu Kristi, gbogbo ènìyàn àti gbogbo àwọn ó gbàgbọ́, nítorí ìyàtọ̀ láàrín Júù àti Helleni. 23 3.23: Ro 3.9.Gbogbo ènìyàn ni ó ṣá ti ṣẹ̀, wọ́n kùnà ògo Ọlọ́run, 24 3.24: Ro 4.16; 5.9; Ef 2.8; Tt 3.7; Ef 1.7; Kl 1.14; Hb 9.15.àwọn ẹni a ń láre lọ́fẹ̀́ nípa oore-ọ̀fẹ́ rẹ̀, nípa ìdáǹdè ó nínú Kristi Jesu. 25 Ẹni Ọlọ́run ti gbé kalẹ̀ láti jẹ́ ètùtù nípa ìgbàgbọ́ nípa ̀jẹ̀ rẹ̀, láti fi òdodo rẹ̀ hàn nítorí ìdáríjì àwọn ̀ṣẹ̀ ó ti kọjá, nínú ìpamọ́ra Ọlọ́run, 26 3.26: 1Jh 2.2; Kl 1.20.láti fi òdodo rẹ̀ hàn ìgbà ìsinsin yìí: ó jẹ́ olódodo àti olùdáláre ẹni ó gba Jesu gbọ́.

27 ̀ìṣògo ? A ti un kúrò. Nípa òfin wo? Nípa iṣẹ́? Bẹ́̀ kọ́, ṣùgbọ́n nípa òfin ìgbàgbọ́. 28 3.28: Ap 13.39; Ro 5.1; Ef 2.9.Nítorí náà, a parí rẹ̀ nípa ìgbàgbọ́ ni a ń ènìyàn láre láìsí iṣẹ́ òfin. 29 3.29: Ro 9.24; Ap 10.34-35.Ọlọ́run àwọn Júù nìkan ha ni ? í ha ṣe ti àwọn aláìkọlà pẹ̀? Bẹ́̀ ni, ti àwọn aláìkọlà pẹ̀. 30 3.30: Ro 4.11-12,16.ó ti jẹ́ Ọlọ́run kan ni, yóò àwọn akọlà láre nípa ìgbàgbọ́ àti àwọn aláìkọlà nípa ìgbàgbọ́ wọn. 31 3.31: Ro 8.4; Mt 5.17.Àwa ha ń sọ òfin dasán nípa ìgbàgbọ́ ? a i, ṣùgbọ́n a ń fi òfin múlẹ̀.

Veja também