Publicidade

Romanos 3

Ìṣòtítọ́ Ọlọ́run

1 Ǹjẹ́ àǹfààní wo Júù ? Tàbí kín ni èrè ilà kíkọ? 2 Púpọ̀ lọ́gbogbo; pàtàkì jùlọ ni àwọn ni a fi ̀rọ̀ Ọlọ́run lọ́wọ́.

3 Ǹjẹ́ ha ni àwọn kan jẹ́ aláìgbàgbọ́? Àìgbàgbọ́ wọn yóò ha sọ òtítọ́ Ọlọ́run di asán ? 4 a ! Ọlọ́run jẹ́ olóòtítọ́, àti olúkúlùkù ènìyàn jẹ́ èké; gẹ́gẹ́ a ti kọ ́ :

"a láre nínú ̀rọ̀ rẹ,

ṣùgbọ́n ìwọ borí nígbà ìwọ ìdájọ́."

5 Ṣùgbọ́n àìṣòdodo wa fi òdodo Ọlọ́run hàn, kín ni àwa ó ? Ọlọ́run ha jẹ́ àìṣòdodo , nígbà ó ń fi ìbínú rẹ̀ hàn? (Mo fi ṣe àkàwé ènìyàn.) 6 a i. bẹ́̀ ni, Ọlọ́run yóò ha ṣe dájọ́ aráyé? 7 Nítorí òtítọ́ Ọlọ́run di púpọ̀ ìyìn rẹ̀ nítorí èké mi, èéṣe a fi ń mi lẹ́jọ́ ẹlẹ́ṣẹ̀? 8 Èéṣe a fi ṣe búburú rere jáde ? àwọn kan ń fi ẹnu àtẹ́ sọ a ń sọ bẹ́̀; ti àwọn kan ń tẹnumọ́ ọn a sọ; àwọn ẹni ìdálẹ́bi wọn tọ́.

olóòtítọ́ kan

9 Ǹjẹ́ ha ni? Àwa ha sàn ju wọn lọ ? bẹ́̀ rárá, nítorí a fihàn ṣáájú àti àwọn Júù àti àwọn Giriki, gbogbo wọn ni ó lábẹ́ ̀ṣẹ̀. 10 Gẹ́gẹ́ a ti kọ ́ ,

"ẹni í ṣe olódodo, ẹnìkan,

11 ẹni òye ,

ẹni ó ń Ọlọ́run.

12 Gbogbo wọn ni ó ti yapa,

wọ́n jùmọ̀ di aláìlérè;

ẹni ń ṣe rere,

tilẹ̀ ẹnìkan."

13 "Ibojì ó ṣí sílẹ̀ ̀fun wọn:

ahọ́n wọn n sọ̀rọ̀ ̀tàn."

"Oró paramọ́lẹ̀ ń bẹ lábẹ́ ètè wọn."

14 "Ẹnu ẹni ó kún fún èpè àti fún oró kíkorò."

15 "Ẹsẹ̀ wọn yára láti ta ̀jẹ̀ sílẹ̀,

16 ìparun àti ìpọ́njú lọ́wọn.

17 ̀àlàáfíà ni wọn mọ̀,"

18 "Ìbẹ̀Ọlọ́run níwájú wọn."

19 Àwa mọ̀ ohunkóhun òfin , ó ń fún àwọn ó lábẹ́ òfin: gbogbo ẹnu à dákẹ́ àti a gbogbo aráyé sábẹ́ ìdájọ́ Ọlọ́run. 20 Nítorí nípa iṣẹ́ òfin, a yóò ẹnikẹ́ni láre níwájú rẹ̀: nítorí nípa òfin ni ìmọ̀ ̀ṣẹ̀ ti .

Ìṣòdodo nípa ìgbàgbọ́

21 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, a ti fi òdodo Ọlọ́run hàn láìsí òfin, a ti ń jẹ́rìí nípa òfin àti nípa àwọn wòlíì, 22 àní òdodo Ọlọ́run nípa ìgbàgbọ́ nínú Jesu Kristi, gbogbo ènìyàn àti gbogbo àwọn ó gbàgbọ́, nítorí ìyàtọ̀ láàrín Júù àti Helleni. 23 Gbogbo ènìyàn ni ó ṣá ti ṣẹ̀, wọ́n kùnà ògo Ọlọ́run, 24 àwọn ẹni a ń láre lọ́fẹ̀́ nípa oore-ọ̀fẹ́ rẹ̀, nípa ìdáǹdè ó nínú Kristi Jesu. 25 Ẹni Ọlọ́run ti gbé kalẹ̀ láti jẹ́ ètùtù nípa ìgbàgbọ́ nípa ̀jẹ̀ rẹ̀, láti fi òdodo rẹ̀ hàn nítorí ìdáríjì àwọn ̀ṣẹ̀ ó ti kọjá, nínú ìpamọ́ra Ọlọ́run, 26 láti fi òdodo rẹ̀ hàn ìgbà ìsinsin yìí: ó jẹ́ olódodo àti olùdáláre ẹni ó gba Jesu gbọ́.

27 ̀ìṣògo ? A ti un kúrò. Nípa òfin wo? Nípa iṣẹ́? Bẹ́̀ kọ́, ṣùgbọ́n nípa òfin ìgbàgbọ́. 28 Nítorí náà, a parí rẹ̀ nípa ìgbàgbọ́ ni a ń ènìyàn láre láìsí iṣẹ́ òfin. 29 Ọlọ́run àwọn Júù nìkan ha ni ? í ha ṣe ti àwọn aláìkọlà pẹ̀? Bẹ́̀ ni, ti àwọn aláìkọlà pẹ̀. 30 ó ti jẹ́ Ọlọ́run kan ni, yóò àwọn akọlà láre nípa ìgbàgbọ́ àti àwọn aláìkọlà nípa ìgbàgbọ́ wọn. 31 Àwa ha ń sọ òfin dasán nípa ìgbàgbọ́ ? a i, ṣùgbọ́n a ń fi òfin múlẹ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-