Publicidade

Romanos 6

2 a ri! Àwa ẹni ó ti ̀ṣẹ̀, àwa ó ha ṣe láààyè nínú rẹ̀ mọ́? 3 Tàbí ẹyin mọ gbogbo wa ti a ti bamitiisi wa sínú Jesu Kristi ni a ti bamitiisi sínú ikú rẹ. 4 Nítorí náà, a sin wa pẹ̀Kristi nípa ìtẹ̀bọmi si ikú, ó le jẹ́ pe a ti Kristi dìde pẹ̀ògo Baba, àwa pẹ̀gbé ìgbé ayé tuntun.

5 Nítorí ̀yin ti di ̀kan ṣoṣo pẹ̀rẹ̀, àti pẹ̀rẹ̀, nígbà òun . Nísinsin yìí, ń pín ìyè tuntun rẹ̀, ̀yin yóò dìde gẹ́gẹ́ òun náà ti dìde. 6 Gbogbo èrò búburú ọkàn yín ni a kàn mọ́ àgbélébùú pẹ̀rẹ̀. ̀̀ṣẹ̀ ó ń fẹ́ láti máa dẹ́ṣẹ̀ nínú yín ni a ti sọ di aláìlera. Nítorí náà, ara yín ó ń fẹ́ láti máa dẹ́ṣẹ̀ lábẹ́ àkóso ̀ṣẹ̀ mọ́, láti jẹ́ ẹrú fún ̀ṣẹ̀ mọ́. 7 Nítorí nígbà ti di òkú fún ̀ṣẹ̀, a ti gbà yín sílẹ̀ kúrò lọ́wọ́ gbogbo agbára ̀ṣẹ̀. ̀ṣẹ̀ agbára lórí yín mọ́.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-