Publicidade

Romanos 8

35 Ta ni yóò ha kúrò nínú ìfẹ́ Kristi? Ìpọ́njú ni, tàbí wàhálà tàbí inúnibíni tàbí ìyàn, tàbí ìhòhò, tàbí ewu tàbí idà? 36 8.36: Sm 44.22.Gẹ́gẹ́ a ti kọ ́ :

"Nítorí rẹ̀ ni a ṣe ń pa gbogbo ọjọ́;

À ń àgùntàn fún pípa."

37 8.37: 1Kọ 15.57. Ṣùgbọ́n nínú gbogbo nǹkan wọ̀nyí, àwa ju ẹni ó ṣẹ́gun lọ nípasẹ̀ Kristi ẹni ó fẹ́ wa. 38 Nítorí ó mi lójú gbangba , í ṣe ikú tàbí ìyè, í ṣe àwọn angẹli tàbí ̀èṣù, í ṣe ohun ìgbà ìsinsin yìí tàbí ohun ó ń bọ̀, tàbí àwọn agbára, 39 tàbí òkè, tàbí ̀gbun, tàbí ohunkóhun nínú ìṣẹ̀ni yóò le kúrò nínú ìfẹ́ Ọlọ́run ó ń bẹ nínú Kristi Jesu, Olúwa wa.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-