Publicidade

Tito 2

Àwọn ̀kọ́ a gbọdọ̀ kọ́ onírúurú àkójọpọ̀

1 Ṣùgbọ́n ìwọ gbọdọ̀ máa kọ́ni ̀kọ́ ó kooro lórí ìgbé ayé onígbàgbọ́ tòótọ́. 2 Kọ́ àwọn àgbà ọkùnrin lẹ́kọ̀́ láti ìrònú àti láti jẹ́ ẹni àpọ́nlé àti ẹni ìwọ̀ntúnwọ̀nsì. Wọn gbọdọ̀ jẹ́ ẹni ó jinlẹ̀ nínú ìgbàgbọ́, nínú ìfẹ́ àti nínú ìpamọ́ra.

3 Bákan náà, ni ó kọ́ àwọn àgbà obìnrin lẹ́kọ̀́ láti kọ́ à a gbé ìgbé ayé ẹni ̀wọ̀, wọn gbọdọ̀ jẹ́ afọ̀rọ̀kẹ́lẹ́ batẹnijẹ́ tàbí olùfẹ́ ọtí mímu, ṣùgbọ́n wọ́n gbọdọ̀ jẹ́ olùkọ́ni ohun rere. 4 Nípa èyí, wọ́n yóò máa kọ́ àwọn ̀dọ́bìnrin láti nífẹ̀́ àwọn ọkọ wọn àti àwọn ọmọ wọn, 5 láti jẹ́ ẹni ìwọ̀ntúnwọ̀nsì àti ọlọ́kàn mímọ́, wọ́n máa ṣe ojúṣe wọn nínú ilé, wọ́n gbọdọ̀ jẹ́ onínúrere, wọ́n máa tẹríba fún àwọn ọkọ wọ́n, ẹnikẹ́ni máa ba à sọ̀rọ̀-òdì ̀rọ̀ Ọlọ́run.

6 Bákan náà, rọ àwọn ̀dọ́ ọkùnrin láti ara wọn ni ìjánu. 7 Nínú ohun gbogbo fi ara rẹ̀ hàn gẹ́gẹ́ alápẹẹrẹ ohun rere. Nínú ̀kọ́ rẹ fi àpẹẹrẹ ìwà pípé hàn, ẹni kún ojú òsùwọ̀n 8 ̀rọ̀ ó kooro, a lẹ́bi, ojú ó ti ẹni ó ń sòdì, àìní ohun búburú kan láti wa.

9 Kọ́ àwọn ẹrú láti ṣe ìgbọ́ràn àwọn olówó wọn nínú ohun gbogbo, láti máa gbìyànjú láti tẹ́ wọn lọ́rùn, wọn gbọdọ̀ gbó olówó wọn lẹ́nu, 10 wọn gbọdọ̀ wọ́n lólè ohunkóhun, ṣùgbọ́n wọ́n jẹ́ ẹni ṣe é gbẹ́kẹ̀, wọn ó làkàkà gbogbo ̀láti jẹ́ ìkọ́ni nípa Ọlọ́run àti Olùgbàlà ìtumọ̀ rere.

11 Nítorí oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run ìgbàlà ti fi ara hàn fún gbogbo ènìyàn. 12 Ó ń kọ́ wa láti sẹ́ àìwà-bí-Ọlọ́run àti ìfẹ́kúfẹ̀́ ayé, a máa àìrékọjá, òdodo àti ìwà-bí-Ọlọ́run ayé ìsinsin yìí, 13 a ti ń wọ́fún ìrètí bùkún, èyí ń ìfarahàn ògo Ọlọ́run wa ó tóbi àti Olùgbàlà wa Jesu Kristi. 14 Ẹni ó fi ara rẹ̀ fún wa láti fún ìràpadà kúrò nínú ìwà búburú gbogbo àti ó le wẹ̀ àwọn ènìyàn kan mọ́ fún ara rẹ̀ fún ìní ohun tìkára rẹ̀, àwọn ń ìtara fún iṣẹ́ rere.

15 Àwọn nǹkan wọ̀nyí ni ìwọ ó máa kọ wọn. Gbani níyànjú ó máa fi gbogbo àṣẹ ni . Máa jẹ́ ẹnikẹ́ni ó gàn ́.

Veja também

Publicidade
Tito
Ver todos os capítulos de Tito
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-