Publicidade

Corpo é o templo de Deus

Por Bíblia Online

O corpo do cristão é templo de Deus. Ele habita em nós pelo Espírito Santo, fazendo do crente morada viva e sagrada do Altíssimo.

Templo do Deus vivo

Vós sois o templo do Deus vivo. Deus disse: habitarei neles e entre eles andarei. O criador mora em sua criação redimida.

Ṣé ̀yin tilẹ̀ mọ̀ tẹmpili Ọlọ́run ni ̀yin jẹ́? Àti pẹ̀pe ̀Ọlọ́run ń gbé inú yín? ẹnikẹ́ni ba tẹmpili Ọlọ́run jẹ́, òun ni Ọlọ́run yóò parun; nítorí mímọ́ ni tẹmpili Ọlọ́run, èyí ̀yin jẹ́.

Tàbí, ̀yin mọ̀ ara yín ni tẹmpili ̀Mímọ́, ti ń bẹ nínú yín, ti ̀yin ti gbà lọ́wọ́ Ọlọ́run? ̀yin í ṣe ti ara yín, nítorí a ti yín ni iye kan. Nítorí náà yìn Ọlọ́run lógo nínú ara yín, àti nínú ̀yín, í ṣe ti Ọlọ́run.

Ìrẹ́pọ̀ kín ni tẹmpili Ọlọ́run pẹ̀òrìṣà? Nítorí ̀yin tẹmpili Ọlọ́run alààyè; gẹ́gẹ́ Ọlọ́run ti :

"Èmi á gbé inú wọn,

èmi o máa rìn láàrín wọn,

èmi ó jẹ́ Ọlọ́run wọn,

wọn yóò jẹ́ ènìyàn mi."

Ǹjẹ́ nítorí náà ̀yin í ṣe àlejò àti àjèjì mọ́, ṣùgbọ́n àjùmọ̀jogún ọmọ ìbílẹ̀ pẹ̀àwọn ènìyàn mímọ́, àti àwọn ará ilé Ọlọ́run; a ń gbé yín lórí ìpìlẹ̀ àwọn aposteli, àti àwọn wòlíì, pẹ̀Jesu Kristi fúnra rẹ̀ gẹ́gẹ́ pàtàkì òkúta igun ilé. Nínú rẹ ni gbogbo ilé náà, a ń kọ papọ̀ ṣọ̀kan ó ń dàgbàsókè láti di tẹmpili mímọ́ kan nínú Olúwa. Nínú rẹ̀ ni a ń gbé ̀yin pẹ̀pẹ̀fún ibùjókòó Ọlọ́run nínú ̀rẹ̀.

Láti ọwọ́ ènìyàn kan ni a à ti kọ́ olúkúlùkù ilé; ṣùgbọ́n ẹni ó kọ́ ohun gbogbo ni Ọlọ́run. Mose nítòótọ́ ṣe olóòtítọ́ nínú gbogbo iṣẹ́ rẹ̀ nínú ilé Ọlọ́run, ìránṣẹ́, fún ̀ohun a ó sọ̀rọ̀ wọ́n ìgbà ìkẹyìn. Ṣùgbọ́n Kristi jẹ́ olóòtítọ́ gẹ́gẹ́ ọmọ lórí ilé Ọlọ́run; ilé ẹni àwa jẹ́, àwa gbẹ́kẹ̀e, a di ìṣògo ìrètí wa mu ṣinṣin títí òpin.

Mose nítòótọ́ ṣe olóòtítọ́ nínú gbogbo iṣẹ́ rẹ̀ nínú ilé Ọlọ́run, ìránṣẹ́, fún ̀ohun a ó sọ̀rọ̀ wọ́n ìgbà ìkẹyìn. Ṣùgbọ́n Kristi jẹ́ olóòtítọ́ gẹ́gẹ́ ọmọ lórí ilé Ọlọ́run; ilé ẹni àwa jẹ́, àwa gbẹ́kẹ̀e, a di ìṣògo ìrètí wa mu ṣinṣin títí òpin.

Cristo em nós

Já não sou eu quem vive, mas Cristo vive em mim. A presença de Deus no crente é privilégio e responsabilidade sagrada.

A ti kàn mọ́ àgbélébùú pẹ̀Kristi, èmí láààyè mọ́, ṣùgbọ́n Kristi ń gbé inú mi wíwà mo láààyè nínú ara, mo láààyè nínú ìgbàgbọ́ Ọmọ Ọlọ́run, ẹni o fẹ́ mi, ó fi òun tìkára rẹ̀ fún mi.

Jesu dáhùn ó fún un , "ẹnìkan fẹ́ràn mi, yóò pa ̀rọ̀ mi mọ́. Baba mi yóò fẹ́ràn rẹ̀, àwa ó tọ̀ ́ , a ó ṣe ibùgbé wa pẹ̀rẹ̀.

Ìpè ìforítì

Ará, ǹjẹ́ a ti ìgboyà láti wọ inú Ibi Mímọ́ Jùlọ nípasẹ̀ ̀jẹ̀ Jesu, nípa ̀títún àti ààyè, o mímọ́ fún wa, àti láti kọjá aṣọ ìkélé èyí yìí , ara rẹ̀; àti a ti ni àlùfáà gíga lórí ilé Ọlọ́run; jẹ́ a fi òtítọ́ ọkàn súnmọ́ tòsí ni ̀kún ìgbàgbọ́, a wẹ ọkàn wa mọ́ kúrò nínú ̀ọkàn búburú, a fi omi mímọ́ wẹ ara wa .

Ṣùgbọ́n ̀yin ni ìran a yàn olú àlùfáà, Orílẹ̀-èdè mímọ́, ènìyàn ̀tọ̀ ki ̀yin fi ọláńlá ẹni ó yín jáde kúrò nínú òkùnkùn sínú ìmọ́lẹ̀ ìyanu rẹ̀ hàn.

Seja o primeiro
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-