Publicidade

1 Coríntios 6

Ìyànjú èdè-àìyedè àwọn onígbàgbọ́

1 ẹnikẹ́ni nínú yín ni èdè-àìyedè ẹnìkejì rẹ̀, ó ha gbọdọ̀ lọ é lẹ́jọ́ níwájú àwọn aláìṣòótọ́ , ṣe níwájú àwọn ènìyàn mímọ́? 2 Ṣé ̀yin mọ̀ àwọn ẹni mímọ́ ni yóò ṣe ìdájọ́ ayé? Ǹjẹ́ ó ba ṣe ìpàṣẹ yín ni a o ti ṣe ìdájọ́ ayé, kín ni ìdí fi yanjú àwọn ̀rọ̀ kéékèèké wọ̀nyí láàrín ara yín. 3 mọ̀ àwa ni a ó ṣe ìdájọ́ àwọn angẹli ? Mélòó mélòó àwọn nǹkan nínú ayé yìí. 4 Nítorí náà, ̀yin ni aáwọ̀ lórí ̀rọ̀ yìí, ǹjẹ́ ó yàn láti gba ìdájọ́ lọ́dọ̀ àwọn ìgbé ayé wọn ń di gígàn nínú ìjọ. 5 Mo sọ èyí ojú yín. Ṣé ó ṣe é ṣe a máa rín ẹnìkan láàrín yín ó gbọ́n níwọ̀n láti ṣe ìdájọ́ èdè-àìyedè láàrín àwọn onígbàgbọ́? 6 Ṣùgbọ́n dípò èyí, arákùnrin kan ń pe arákùnrin kejì lẹ́jọ́ ilé ẹjọ́ níwájú àwọn aláìgbàgbọ́.

7 Ǹjẹ́ nísinsin yìí, àbùkù ni fún un yín pátápátá ̀yin ń ara yín ṣe ẹjọ́. Kín ṣe kúkú gba ìyà? Kín kúkú gba ìrẹ́jẹ fi i sílẹ̀ bẹ́̀? 8 Ṣùgbọ́n ̀yin ń jẹ ni ìyà, ń rẹ́ ni jẹ. ̀yin si ń ṣe èyí àwọn arákùnrin yín. 9 ̀yin mọ̀ àwọn aláìṣòótọ́ í yóò jogún ìjọba Ọlọ́run? a máa tàn yín jẹ; í ṣe àwọn àgbèrè, tàbí àwọn abọ̀rìṣà, tàbí àwọn panṣágà, tàbí àwọn ọkùnrin ń ṣe ìṣe obìnrin tàbí àwọn ọkùnrin ń ba ara wọn lòpọ̀ 10 tàbí àwọn olè, tàbí àwọn wọ̀bìà, tàbí àwọn ̀mùtí, tàbí àwọn apẹ̀gàn, tàbí àwọn alọ́nilọ́wọ́gbà ni yóò jogún ìjọba Ọlọ́run. 11 Bẹ́̀ ni àwọn ẹlòmíràn nínú yín jẹ́ ; ṣùgbọ́n a ti sọ yín di mímọ́, ṣùgbọ́n a ti yín láre ni orúkọ Jesu Kristi Olúwa, àti nípa ̀Mímọ́ Ọlọ́run wa.

Ìwà àgbèrè

12 "Ohun gbogbo ó tọ́ fún mi," ṣùgbọ́n í ṣe ohun gbogbo ni ó èrè. "Ohun gbogbo ni ó yẹ fún mi," ṣùgbọ́n èmi yóò jẹ́ ohunkóhun ṣe olórí fun mi. 13 "Oúnjẹ fún inú àti inú fún oúnjẹ," ṣùgbọ́n Ọlọ́run yóò fi òpin méjèèjì, ara í ṣe fún ìwà àgbèrè ṣíṣe, ṣùgbọ́n fún Olúwa, àti Olúwa fún ara náà. 14 Nínú agbára rẹ̀, Ọlọ́run Olúwa dìde kúrò nínú òkú bẹ́̀ gẹ́gẹ́ ni yóò àwa náà dìde. 15 Ṣé tilẹ̀ mọ̀ ara yín gan an jẹ́ ̀ara Kristi fún ara rẹ̀? Ǹjẹ́ ó ba jẹ́ bẹ́̀, ǹjẹ́ ó yẹ ń ̀ara Kristi ń fi ṣe ̀ara àgbèrè ? a i! 16 Tàbí mọ̀ ẹnìkan so ara rẹ̀ pọ̀ mọ́ àgbèrè ó jẹ́ ara kan pẹ̀rẹ̀? Nítorí a kọ ́ , "Àwọn méjèèjì yóò di ara kan." 17 Ṣùgbọ́n ẹni ti ó dàpọ̀ mọ́ Olúwa di ̀kan náà pẹ̀rẹ̀.

18 máa fún àgbèrè. Gbogbo ̀ṣẹ̀ ènìyàn ń lóde ara, ṣùgbọ́n ẹni ń ṣe àgbèrè ń ṣe ara òun tìkára rẹ̀. 19 Tàbí, ̀yin mọ̀ ara yín ni tẹmpili ̀Mímọ́, ti ń bẹ nínú yín, ti ̀yin ti gbà lọ́wọ́ Ọlọ́run? ̀yin í ṣe ti ara yín, 20 nítorí a ti yín ni iye kan. Nítorí náà yìn Ọlọ́run lógo nínú ara yín, àti nínú ̀yín, í ṣe ti Ọlọ́run.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-