Publicidade

Tomar uma decisão

Por Bíblia Online

Tomar decisões com sabedoria é um dos maiores desafios da vida. A Bíblia nos ensina a buscar a Deus em oração, na Palavra e no conselho, confiando que Ele dirige os nossos passos.

Buscar a Deus

Se algum de vós tem falta de sabedoria, peça a Deus. Ele dá generosamente e sem repreensão a todos os que pedem.

ó ku ọgbọ́n fún ẹnikẹ́ni, ó béèrè lọ́wọ́ Ọlọ́run ẹni fi fún gbogbo ènìyàn ̀pọ̀lọpọ̀, í ka àlébù ; a ó fi fún un.

Èyí ni ìgboyà àwa níwájú rẹ̀, àwa béèrè ohunkóhun gẹ́gẹ́ ìfẹ́ rẹ̀, ó ń gbọ́ wa.

àwa jẹ́wọ́ ̀ṣẹ̀ wa, olóòtítọ́ àti olódodo ni òun láti dárí ̀ṣẹ̀ wa , àti láti wẹ̀ kúrò nínú àìṣòdodo gbogbo.

Gbẹ́kẹ̀Olúwa pẹ̀gbogbo ọkàn rẹ

ṣe sinmi òye ara à rẹ.

Mọ̀ ́n gbogbo ̀rẹ

òun yóò máa tọ́ ipa ̀rẹ.

Mọ̀ ́n gbogbo ̀rẹ

òun yóò máa tọ́ ipa ̀rẹ.

Nítorí mo mọ èrò mo yín," ni Olúwa , "àní èrò àlàáfíà, í ṣe fún ibi, èrò láti fún un yín ìgbà ìkẹyìn àti ìrètí ọjọ́ iwájú.

Conselho e direção

Onde não há conselho os planos se frustam. Toda Escritura é útil para nos guiar nas decisões da vida.

Nítorí àìní ìtọ́sọ́orílẹ̀-èdè ṣubú

ṣùgbọ́n nípasẹ̀ ̀pọ̀lọpọ̀ olùbádámọ̀ràn ìṣẹ́gun dájú.

A ṣẹ́ kèké si ìṣẹ́po aṣọ,

ṣùgbọ́n gbogbo ìdájọ́ rẹ̀ láti ̀dọ̀ Olúwa.

Ènìyàn ba ni rẹ́ a máa lépa ìmọ̀ ara rẹ̀;

ó kọjú ìjà gbogbo ìdájọ́ òdodo.

Aláìgbọ́n inú dídùn òye

ṣùgbọ́n ó inú dídùn sísọ èrò tirẹ̀.

Nígbà ti ènìyàn búburú ni ̀gàn ,

nígbà ti ̀gàn ni ìtìjú .

̀rọ̀ ẹnu ènìyàn jẹ́ omi jíjìn,

ṣùgbọ́n orísun ọgbọ́n jẹ́ odò ń sàn.

dára ènìyàn ṣe ojúsàájú fún ènìyàn búburú

tàbí a fi ìdájọ́ òdodo du aláìṣẹ̀.

Ètè aláìgbọ́n ìjà sílẹ̀

ẹnu rẹ̀ ń ṣokùnfà ẹgba.

Ẹnu aláìgbọ́n ni ó ba tirẹ̀ jẹ́,

ètè rẹ̀ jẹ́ ìdẹ̀kùn fún ọkàn rẹ̀.

̀rọ̀ olófòófó dàbí oúnjẹ àdídùn;

wọ́n a wọ ìsàlẹ̀ inú lọ.

Ẹni ṣe déédé nínú iṣẹ́ rẹ̀

arákùnrin jẹ́ fún apanirun.

Orúkọ Olúwa, ilé ìṣọ́ agbára ni;

olódodo wọ inú rẹ̀, ó ìgbàlà.

̀rọ̀ olówó ni ìlú olódi wọn;

wọ́n ó i odi ṣe é gùn ni.

Ṣáájú ìṣubú ọkàn ènìyàn a kọ́kọ́ máa gbéraga,

ṣùgbọ́n ìrẹ̀lẹ̀ ni ó máa ń ṣáájú ọlá.

Ẹni ó ń fèsì ó gbọ́,

èyí ni ìwà òmùgọ̀ àti ìtìjú rẹ̀.

Ọkàn ènìyàn a máa gbé e nígbà àìsàn,

ṣùgbọ́n ta ni ó le forí ti ọkàn ó rẹ̀wẹ̀.

Gbogbo ìwé mímọ́ ni ó ìmísí Ọlọ́run ó èrè fún ̀kọ́, fún ìbániwí, fún ìtọ́ni, fún ìkọ́ni ó nínú òdodo.

ènìyàn Ọlọ́run , a ti múra sílẹ̀ pátápátá fun iṣẹ́ rere gbogbo.

Nígbà wọ́n ̀kánkán Misia, wọ́n gbìyànjú láti lọ Bitinia, ṣùgbọ́n ̀Jesu gbà fún wọn.

Àwọn wòlíì àti àwọn olùkọ́ni ń bẹ nínú ìjọ ti ó ni Antioku; Barnaba àti Simeoni a ń ni Nigeri, àti Lukiu ará Kirene, àti Manaeni (ẹni a tọ́ pọ̀ pẹ̀Herodu tetrarki) àti Saulu. wọn ti ń jọ́sìn fún Olúwa, wọ́n ń gbààwẹ̀, ̀Mímọ́ , "ya Barnaba àti Saulu sọ́tọ̀ fún mi fún iṣẹ́ ti mo ti wọ́n !" Nígbà wọ́n ti gbààwẹ̀, wọn ti gbàdúrà, wọ́n gbé ọwọ́ wọn, wọ́n rán wọn lọ.

Confiar e seguir

Seja o que for que façais, fazei tudo para a glória de Deus. O sábio ouve a Deus antes de agir.

Nítorí náà ̀yin jẹ tàbí mu tàbí ohunkóhun ̀yin , e máa ṣe gbogbo rẹ̀ fún ògo Ọlọ́run.

Ìbáwí àwọn Ọmọ Ọlọ́run

Nítorí náà a ti fi ìkùùkuu àwọsánmọ̀ o kún fún àwọn ẹlẹ́rìí báyìí wa , jẹ́ a pa ohun ìdíwọ́ gbogbo apá kan, àti ̀ṣẹ̀ o rọrùn láti di mọ́ wa, a máa fi sùúrù súré ìje a gbé ka iwájú wa,

Gibeoni, Olúwa fi ara han Solomoni lójú àlá òru, Ọlọ́run , "Béèrè fún ohunkóhun o ń fẹ́ èmi ó fi fún ."

Solomoni dáhùn , "O ti fi inú rere oore ńlá hàn ìránṣẹ́ rẹ, Dafidi baba mi, nítorí ó jẹ́ olóòtítọ́ àti olódodo àti ẹni ó ọkàn ìdúró ṣinṣin. Ìwọ tẹ̀síwájú nínú oore ńlá yìí fún un, ìwọ ti fún un ọmọkùnrin láti jókòó lórí ìtẹ́ rẹ gbogbo ọjọ́.

"Nísinsin yìí, Olúwa Ọlọ́run mi, o ti ìránṣẹ́ rẹ jẹ ọba ipò Dafidi baba mi. Ṣùgbọ́n ọmọ kékeré ni , èmi mọ jíjáde àti wíwọlé mi. Ìránṣẹ́ rẹ nìyí láàrín àwọn ènìyàn o ti yàn, àwọn ènìyàn ńlá, wọ́n pọ̀ bẹ́̀ a wọ́n tàbí mọye wọn. Nítorí náà fi ọkàn ìmòye fún ìránṣẹ́ rẹ láti le ṣàkóso àwọn ènìyàn rẹ àti láti mọ ìyàtọ̀ láàrín rere àti búburú. Nítorí ta ni ó ṣe àkóso àwọn ènìyàn ńlá rẹ yìí?"

Inú Olúwa dùn Solomoni béèrè nǹkan yìí. Nígbà náà ni Ọlọ́run fún un , "Nítorí ìwọ ti béèrè fún èyí, í ṣe ̀gígùn tàbí ọrọ̀ fún ara rẹ, tàbí béèrè fún ikú àwọn ̀rẹ, ṣùgbọ́n fún òye láti mọ ẹjọ́ , èmi yóò ṣe ohun ìwọ ti béèrè. Èmi yóò fún ọgbọ́n àti ọkàn ìmòye, bẹ́̀ fi ẹnìkan ó dàbí rẹ ṣáájú rẹ, bẹ́̀ ni ẹnìkan yóò dìde yóò dàbí rẹ lẹ́yìn rẹ.

Nígbà náà ni aya rẹ̀ fún un , "Ìwọ di ìwà òtítọ́ síbẹ̀! Ọlọ́run, ó !"

Ṣùgbọ́n ó a lóhùn , "Ìwọ sọ̀rọ̀ ̀kan lára àwọn aṣiwèrè obìnrin ti í sọ̀rọ̀; ! Àwa yóò ha gba ìre lọ́wọ́ Ọlọ́run, a gba ibi?"

Nínú gbogbo èyí, Jobu fi ètè rẹ̀ ṣẹ̀.

Seja o primeiro
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_15-35-42-