Publicidade

1 Reis 3

Solomoni béèrè fún ọgbọ́n

1 Solomoni Farao ọba Ejibiti àna, ó fẹ́ ọmọbìnrin rẹ̀ ìyàwó. Ó un ìlú Dafidi títí ó fi parí kíkọ́ ààfin rẹ̀ àti tẹmpili Olúwa, àti odi ó Jerusalẹmu . 2 Síbẹ̀síbẹ̀, àwọn ènìyàn ṣì ń ẹbọ ibi gíga, nítorí a ì kọ́ ilé fún orúkọ Olúwa títí di ìgbà náà 3 Solomoni fi ìfẹ́ rẹ̀ hàn Olúwa nípa rírìn gẹ́gẹ́ òfin Dafidi baba rẹ̀, àti , ó ẹbọ, ó fi tùràrí jóná ibi gíga.

4 3.4-15: 2Ki 1.3-13. Ọba lọ Gibeoni láti ẹbọ, nítorí ibẹ̀ ni ibi gíga ó ṣe pàtàkì , Solomoni ẹgbẹ̀rún (1,000) ọrẹ ẹbọ sísun lórí pẹpẹ. 5 Gibeoni, Olúwa fi ara han Solomoni lójú àlá òru, Ọlọ́run , "Béèrè fún ohunkóhun o ń fẹ́ èmi ó fi fún ."

6 Solomoni dáhùn , "O ti fi inú rere oore ńlá hàn ìránṣẹ́ rẹ, Dafidi baba mi, nítorí ó jẹ́ olóòtítọ́ àti olódodo àti ẹni ó ọkàn ìdúró ṣinṣin. Ìwọ tẹ̀síwájú nínú oore ńlá yìí fún un, ìwọ ti fún un ọmọkùnrin láti jókòó lórí ìtẹ́ rẹ gbogbo ọjọ́.

7 "Nísinsin yìí, Olúwa Ọlọ́run mi, o ti ìránṣẹ́ rẹ jẹ ọba ipò Dafidi baba mi. Ṣùgbọ́n ọmọ kékeré ni , èmi mọ jíjáde àti wíwọlé mi. 8 Ìránṣẹ́ rẹ nìyí láàrín àwọn ènìyàn o ti yàn, àwọn ènìyàn ńlá, wọ́n pọ̀ bẹ́̀ a wọ́n tàbí mọye wọn. 9 Nítorí náà fi ọkàn ìmòye fún ìránṣẹ́ rẹ láti le ṣàkóso àwọn ènìyàn rẹ àti láti mọ ìyàtọ̀ láàrín rere àti búburú. Nítorí ta ni ó ṣe àkóso àwọn ènìyàn ńlá rẹ yìí?"

10 Inú Olúwa dùn Solomoni béèrè nǹkan yìí. 11 Nígbà náà ni Ọlọ́run fún un , "Nítorí ìwọ ti béèrè fún èyí, í ṣe ̀gígùn tàbí ọrọ̀ fún ara rẹ, tàbí béèrè fún ikú àwọn ̀rẹ, ṣùgbọ́n fún òye láti mọ ẹjọ́ , 12 èmi yóò ṣe ohun ìwọ ti béèrè. Èmi yóò fún ọgbọ́n àti ọkàn ìmòye, bẹ́̀ fi ẹnìkan ó dàbí rẹ ṣáájú rẹ, bẹ́̀ ni ẹnìkan yóò dìde yóò dàbí rẹ lẹ́yìn rẹ. 13 Síwájú i, èmi yóò fi ohun ìwọ béèrè fún : ọrọ̀ àti ọlá gbogbo ayé rẹ, yóò ẹnìkan nínú àwọn ọba yóò dàbí rẹ. 14 Àti ìwọ rìn ̀mi, o pa òfin àti àṣẹ mi mọ́ Dafidi baba rẹ ti ṣe, èmi yóò fún ̀gígùn." 15 Solomoni : ó mọ̀ àlá ni.

Ó padà Jerusalẹmu, ó dúró níwájú àpótí ̀Olúwa, ó ẹbọ sísun àti ẹbọ àlàáfíà. Nígbà náà ni ó ṣe àsè fún gbogbo àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀.

Ìdájọ́ ọgbọ́n

16 Lẹ́yìn náà ni àwọn obìnrin alágbèrè méjì sọ́dọ̀ ọba, wọ́n dúró níwájú rẹ̀. 17 ̀kan nínú wọn , "Olúwa mi, èmi àti obìnrin yìí ń gbé nínú ilé kan. Èmi ọmọ ilé pẹ̀rẹ̀. 18 ọjọ́ kẹta lẹ́yìn ìgbà mo bímọ tan, obìnrin yìí bímọ pẹ̀. A nìkan ; àlejò ilé ṣe àwa méjèèjì nìkan.

19 "òru, ọmọ obìnrin yìí nítorí ó sùn e. 20 Nígbà náà ni ó dìde ̀gànjọ́, ó gbé ọmọ tèmi lẹ́gbẹ̀́ mi, nígbà èmi ìránṣẹ́ rẹ̀ ti sùn lọ. Ó tẹ́ àyà rẹ̀, ó tẹ́ òkú ọmọ tirẹ̀ àyà mi. 21 òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, mo dìde láti fi ọmú fún ọmọ mi: ó ti ! Ṣùgbọ́n, nígbà mo ó fín òwúrọ̀, mo i í ṣe ọmọ mi mo ."

22 Obìnrin kejì , "Bẹ́̀ kọ́! Èyí alààyè ni ọmọ mi, èyí òkú ni ọmọ tirẹ̀." Èyí òkú ni tirẹ̀; èyí alààyè ni tèmi.

Ṣùgbọ́n èyí àkọ́kọ́ tún , "Bẹ́̀ kọ́! Èyí òkú ni tìrẹ; èyí alààyè ni tèmi." Báyìí ni wọ́n ń jiyàn níwájú ọba.

23 Ọba , "Ẹni yìí , Ọmọ mi ni ó láààyè, ọmọ tirẹ̀ ni ó ,nígbà ẹni èkejì náà ń , Bẹ́̀ kọ́! Ọmọ tirẹ̀ ni ó , ọmọ tèmi ni ó láààyè.’ "

24 Nígbà náà ni ọba , "idà fún mi ." Bẹ́̀ ni wọ́n idà fún ọba. 25 Ọba pàṣẹ , "alààyè ọmọ méjì, ìdajì fún ̀kan, àti ìdajì fún èkejì."

26 Obìnrin ọmọ tirẹ̀ láààyè kún fún àánú fún ọmọ rẹ̀, ó fún ọba , "Jọ̀wọ́, olúwa mi, fún un alààyè ọmọ! ṣe pa á!"

Ṣùgbọ́n obìnrin èkejì , "yóò jẹ́ tèmi tàbí tìrẹ. e méjì!"

27 Nígbà náà ni ọba dáhùn, ó , "fi alààyè ọmọ fún obìnrin àkọ́kọ́. ṣe pa á: òun ni ìyá rẹ̀."

28 Nígbà gbogbo Israẹli gbọ́ ìdájọ́ ọba ṣe, wọ́n bẹ̀níwájú ọba, nítorí wọ́n ti í ó ọgbọ́n láti ̀dọ̀ Ọlọ́run láti ṣe ìdájọ́.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_21-26-40-