Publicidade

1 Coríntios 10

Ìkìlọ̀ láti inú ìtàn àwọn ọmọ Israẹli

1 Nítorí èmi fẹ́ ̀yin jẹ́ òpè si òtítọ́, ̀yin arákùnrin ̀wọ́n, a gbọdọ̀ gbàgbé ohun ó ṣẹlẹ̀ àwọn ènìyàn wa nínú aginjù. Ọlọ́run ṣamọ̀wọn nípa rírán ìkùùkuu síwájú wọn, ó sìn wọ́n la omi Òkun pupa . 2 A pe eléyìí ìtẹ̀bọmi ti Mose nínú ìkùùkuu àti nínú omi Òkun. 3 Nípa iṣẹ́ ìyanu, gbogbo wọn jẹ oúnjẹ ̀kan náà. 4 Wọ́n mu nínú omi Kristi fi fún wọn. Wọ́n mu omi ̀láti inú àpáta ó ń tẹ̀wọn, àpáta náà ni Kristi. Ó pẹ̀wọn nínú aginjù náà, òun ni àpáta ń fi omi ̀tu ọkàn lára. 5 Ṣùgbọ́n ̀pọ̀lọpọ̀ wọn ni inú Ọlọ́run dún ; nítorí a pa wọ́n run nínú aginjù.

6 Àwọn nǹkan wọ̀nyí jásí àpẹẹrẹ fún àwa, a ṣe ìfẹ́ àwọn ohun búburú gẹ́gẹ́ àwọn ènìyàn yìí ṣe ìfẹ́ si. 7 ̀yin ó ṣe jẹ́ abọ̀rìṣà gẹ́gẹ́ wọ́n ti ṣe; gẹ́gẹ́ a ti kọ ́ , "Àwọn ènìyàn náà jókòó láti jẹ àti láti mu, wọ́n dìde dúró láti ṣe ìfẹ́kúfẹ̀́." 8 Bẹ́̀ ni àwa ó ṣe ṣe àgbèrè gẹ́gẹ́ àwọn mìíràn nínú wọn ti ṣe, ẹgbẹ̀rún méjìlélógún ó lẹgbẹ̀rún (23,000) ènìyàn ọjọ́ kan. 9 Bẹ́̀ ni ̀yin ṣe dán Olúwa , gẹ́gẹ́ àwọn mìíràn nínú wọn ti dán an , a fi ejò run wọ́n. 10 Bẹ́̀ ni ̀yin ó ṣe kùn, gẹ́gẹ́ àwọn mìíràn nínú wọ́n ṣe kùn, a ti ọwọ́ olùparun run wọ́n.

11 Gbogbo àwọn nǹkan wọ̀nyí ṣẹlẹ̀ wọn àpẹẹrẹ fún wa, a kọ̀wọn fún ìkìlọ̀ fún wa, àwa ẹni ìgbẹ̀yìn ayé . 12 Nítorí náà, ẹni ó òun dúró, ó kíyèsára ó ma ba à ṣubú. 13 ìdánwò kan ó ti yín, ṣe irú èyí ó mọ níwọ̀n fún ènìyàn, ṣùgbọ́n olódodo ni Ọlọ́run, ẹni ti yóò jẹ́ á dán an yín ju ̀yin ti le gbà, ṣùgbọ́n yóò ṣe ̀àbáyọ pẹ̀nínú ìdánwò náà, ̀yin ba à faradà á.

Oúnjẹ òrìṣà àti oúnjẹ alẹ́ Olúwa

14 Nítorí náà, ̀yin olùfẹ́ ̀wọ́n, fún ìbọ̀rìṣà. 15 Èmi ń sọ̀rọ̀ ọlọ́gbọ́n ènìyàn, ṣe ìdájọ́ fúnra rẹ̀ ohun mo sọ. 16 Ǹjẹ́ ago ìdúpẹ́ nípasẹ̀ èyí a ń dúpẹ́ fún, í ha ṣe jíjẹ́ alábápín ìdàpọ̀ nínú ̀jẹ̀ Kristi ? Àkàrà a , í ha ṣe jíjẹ́ alábápín nínú ara Kristi bi? 17 Nítorí àkàrà kan ni ó ń bẹ, àwa a pọ̀ níye, a jẹ ara kan ń pín nínú àkàrà kan ṣoṣo.

18 wo Israẹli nípa ti ara, àwọn ń jẹ ohun ẹbọ ha ṣe alábápín pẹpẹ ? 19 Ǹjẹ́ ni mo ń ? Ṣé ohun a fi ẹbọ òrìṣà jẹ́ nǹkan kan tàbí òrìṣà jẹ́ nǹkan kan? 20 Rárá, ṣùgbọ́n ohun mo ń ni , ohun àwọn aláìkọlà fi ń ẹbọ wọn fi fun àwọn ̀èṣù. Dájúdájú í ṣe ìrúbọ Ọlọ́run. Èmi fẹ́ ẹnikẹ́ni nínú yín so ara rẹ̀ pọ̀ mọ́ ̀èṣù. 21 ̀yin mu nínú ago Olúwa àti ago ti èṣù lẹ́̀kan náà; ̀yin le ṣe àjọpín tábìlì Olúwa, àti ni tábìlì ̀èṣù lẹ́̀kan náà. 22 ni ̀ ń gbìyànjú láti ṣe? Àwa ha ń Olúwa jowú ? Àwa ha agbára ú lọ bi?

Òmìnira àwọn onígbàgbọ́

23 "Ohun gbogbo ni o yẹ fún mi," ṣùgbọ́n í ṣe ohun gbogbo ni ó èrè. "Ohun gbogbo ni ó yẹ fún mi," ṣùgbọ́n í ṣe ohun gbogbo ni ń gbe ni . 24 ṣe ronú nípa ara rẹ̀ nìkan; ṣùgbọ́n olúkúlùkù máa rere ọmọnìkejì rẹ̀.

25 Jẹ ẹrankẹ́ran wọ́n ń lọ́. ṣe gbìyànjú láti wádìí lọ́wọ́ ẹni ń á nítorí ̀ọkàn. 26 Nítorí "Ayé àti gbogbo nǹkan rere ń bẹ nínú rẹ̀, Olúwa ni wọ́n jẹ́."

27 ẹnikẹ́ni í ṣe onígbàgbọ́ ba yín ibi àsè láti jẹun, a lọ. Gba ìpè rẹ̀ ó tẹ́ lọ́rùn. Jẹ ohunkóhun ó pèsè sílẹ̀ fún àsè náà, ṣe béèrè ohunkóhun nípa rẹ̀ nítorí ̀ọkàn. 28 ẹnikẹ́ni kìlọ̀ fún un yín , "A ti fi ẹran yìí ẹbọ," ṣe jẹ́ nítorí ẹni ti o sọ fun àti nítorí ̀ọkàn. 29 Èmi ń sọ̀rọ̀ nípa ̀ọkàn ẹni ó sọ fún í ṣe tirẹ̀. Nítorí kín ni a ó fi mi lẹ́jọ́ nítorí ̀ọkàn ẹlòmíràn. 30 èmi ba fi ọpẹ́ jẹ ́, èéṣe a ń sọ̀rọ̀ mi búburú nítorí ohun èmi dúpẹ́ fún.

31 Nítorí náà ̀yin jẹ tàbí mu tàbí ohunkóhun ̀yin , e máa ṣe gbogbo rẹ̀ fún ògo Ọlọ́run. 32 Nítorí náà, ṣe jẹ́ òkúta ìkọ̀sẹ̀ ó gbé ẹlòmíràn ṣubú ìbá à ṣe Júù tàbí Giriki tàbí ìjọ Ọlọ́run. 33 mo ṣè n gbìyànjú láti tẹ́ ẹnìkọ̀̀kan lọ́rùn nínú gbogbo nǹkan mo ń ṣe láì wa ohun rere fún ara mi ṣe ti ènìyàn púpọ̀ ó ṣe é ṣe fún wọn láti le ìgbàlà.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-