Pular para o conteúdo
Publicidade

Domínio próprio

Por Bíblia Online

O domínio próprio é fruto do Espírito e marca de maturidade espiritual. A Bíblia ensina que quem governa o próprio espírito é melhor do que quem conquista uma cidade.

Fruto do Espírito

O fruto do Espírito inclui domínio próprio. A graça de Deus nos ensina a viver de maneira sóbria e justa neste mundo.

Ṣùgbọ́n èso ti ̀ni ìfẹ́, ayọ̀, àlàáfíà, ìpamọ́ra, ìwà pẹ̀lẹ́, ìṣoore, ìgbàgbọ́, ìwà tútù, àti ìkóra-ẹni níjanu, òfin kan lòdì irú wọ̀nyí,

Nítorí oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run ìgbàlà ti fi ara hàn fún gbogbo ènìyàn. Ó ń kọ́ wa láti sẹ́ àìwà-bí-Ọlọ́run àti ìfẹ́kúfẹ̀́ ayé, a máa àìrékọjá, òdodo àti ìwà-bí-Ọlọ́run ayé ìsinsin yìí, a ti ń wọ́fún ìrètí bùkún, èyí ń ìfarahàn ògo Ọlọ́run wa ó tóbi àti Olùgbàlà wa Jesu Kristi.

Nítorí Ọlọ́run fún wa ni ̀ìbẹ̀, ṣe ti agbára, àti ti ìfẹ́, àti ti ìsẹ́ra-ẹni ti ó kooro.

Àti nítorí ìdí èyí, máa ṣe àìsimi gbogbo, fi ìwà rere kún ìgbàgbọ́, àti ìmọ̀ kún ìwà rere; àti àìrékọjá kún ìmọ̀; àti sùúrù kún àìrékọjá; àti ìwà-bí-Ọlọ́run kún sùúrù. Àti ìfẹ́ ọmọnìkejì kún ìwà-bí-Ọlọ́run; àti ìfẹ́ni kún ìfẹ́ ọmọnìkejì.

Governar a si mesmo

Melhor é o que domina o seu espírito do que o que toma uma cidade. A cidade sem muros é o homem sem domínio próprio.

Ó sàn láti jẹ́ onísùúrù ju ajagun ènìyàn lọ,

ẹni ó pa ìbínú mọ́ra ju ajagun ṣẹ́gun ìlú lọ.

ìlú odi rẹ̀ ti lulẹ̀

ni ènìyàn le ara rẹ̀ ìjánu.

Aláìgbọ́n ènìyàn fi gbogbo ẹnu rẹ̀ bínú

ṣùgbọ́n ọlọ́gbọ́n ènìyàn a máa ìbínú rẹ̀ ìjánu.

Nínú ̀rọ̀ púpọ̀ a le fẹ́ ̀ṣẹ̀

ṣùgbọ́n ẹni ó pa ẹnu rẹ̀ mọ́ jẹ́ ọlọ́gbọ́n.

̀yin mọ̀ , olúkúlùkù ẹni ó ipa nínú eré ìje ni ó máa ń sáré, ṣùgbọ́n ẹnìkan ṣoṣo ni ń gba ipò ̀bùn ó ga . Nítorí náà, eré ìje yín ba à le borí. Gbogbo ẹni ó ń sáré ìje a máa lọ nínú ìsẹ́ra-ẹni ó lágbára. Wọ́n ń ṣe èyí láti gba adé ìdíbàjẹ́. Ṣùgbọ́n àwa ń eré ìje tiwa láti fi gba adé ̀run àìdíbàjẹ́ láéláé. Nítorí náà, mo ń eré ìje lọ sójú àmì, í ṣe ẹni ti lójú. ń n borí, í ṣe ẹni ń afẹ́fẹ́ . Ṣùgbọ́n èmi ń ara mi ìjánu, mo ń un abẹ́ ìtẹríba, lẹ́yìn mo ti wàásù fún àwọn ẹlòmíràn, nítorí ohunkóhun, èmi fún rara mi ṣe di ẹni ìtanù fún ̀bùn náà.

Ṣùgbọ́n wọ́n ara dúró, wọ́n gbéyàwó tàbí wọ́n fẹ́ ọkọ, nítorí ó sàn láti gbéyàwó láti ṣe ìfẹ́kúfẹ̀́ lọ.

ìdánwò kan ó ti yín, ṣe irú èyí ó mọ níwọ̀n fún ènìyàn, ṣùgbọ́n olódodo ni Ọlọ́run, ẹni ti yóò jẹ́ á dán an yín ju ̀yin ti le gbà, ṣùgbọ́n yóò ṣe ̀àbáyọ pẹ̀nínú ìdánwò náà, ̀yin ba à faradà á.

Disciplina e vigilância

Sede sóbrios e vigilantes. O diabo anda em derredor como leão rugidor. A sobriedade nos protege e fortalece.

máa ni àìrékọjá, máa ṣọ́ra; nítorí èṣù ̀yín, i kìnnìún ń ramúramù, ó ń rìn káàkiri, ó ń wa ẹni yóò pajẹ. kọ ojú ìjà i pẹ̀ìdúró ṣinṣin nínú ìgbàgbọ́, ̀yin ti mọ̀ ìyà kan náà ni àwọn ará yín ń bẹ nínú ayé ń jẹ.

Ṣùgbọ́n òpin ohun gbogbo dẹ̀dẹ̀; nítorí náà ̀yin àìrékọjá, máa ṣọ́ra nínú àdúrà.

Ìgbé ayé fún Ọlọ́run

Ǹjẹ́ Kristi ti jìyà fún wa nípa ti ará, irú kan náà ni ̀yin fi hámọ́ra; nítorí ẹni ó ti jìyà nípa ti ara, ó ti bọ́ lọ́wọ́ ̀ṣẹ̀. ̀yin ṣe fi ìgbà ayé yín ìyókù nínú ara mọ́ ìfẹ́kúfẹ̀́ ènìyàn ṣe ìfẹ́ Ọlọ́run. Nítorí ìgbà ó ti kọjá ti fún ṣíṣe ìfẹ́ àwọn aláìkọlà, rínrìn nínú ìwà wọ̀bìà, ìfẹ́kúfẹ̀́, ọtí àmupara, ìréde òru, kíkó ̀gbẹ́ ̀mùtí, àti ìbọ̀rìṣà í ṣe ohun ìríra. Èyí ó wọ́n lẹ́nu ̀yin ba wọn súré sínú irú àṣejù ìwà wọ̀bìà wọ́n, wọ́n ń sọ̀rọ̀ yín búburú. Àwọn ẹni yóò jíyìn fún ẹni ó ti múra láti ṣe ìdájọ́ alààyè àti òkú.

ẹnìkọ̀̀kan yín kọ́ láti ṣàkóso ara rẹ̀ ̀mímọ́ àti pẹ̀ọlá, í ṣe ìfẹ́kúfẹ̀́ gẹ́gẹ́ àwọn aláìkọlà, ẹni mọ Ọlọ́run;

O senhorio de Cristo

Todo domínio pertence a Cristo. Ele é Senhor dos senhores e Rei dos reis — e nos capacita a viver em santidade.

Yin Olúwa, gbogbo iṣẹ́ rẹ̀

ibi gbogbo ìjọba rẹ̀.

Yin Olúwa, ìwọ ọkàn mi.

Ìjọba rẹ ìjọba ayérayé ni,

àti ìjọba rẹ gbogbo ìrandíran.

"Nínú ìran mi òru mo , mo ẹnìkan ó dúró iwájú u mi, ó ọmọ ènìyàn, ó ń bọ̀ nínú àwọsánmọ̀ ̀run, ó ń bọ̀ ̀dọ̀ ẹni ìgbàanì, a u iwájú rẹ̀. A fi ìjọba, ògo àti agbára ilẹ̀ ọba fún un; gbogbo ènìyàn, orílẹ̀-èdè àti èdè gbogbo wọn wólẹ̀ fún un. Ìjọba rẹ̀, ìjọba ayérayé ni, èyí le è kọjá, ìjọba rẹ̀ le è díbàjẹ́ láéláé.

Ó jẹ́ ìdùnnú fún mi láti fi iṣẹ́ àmì àti ìyanu Ọlọ́run ̀gá-Ògo ti ṣe fún mi hàn.

Báwo ni àmì rẹ̀ ti tóbi ,

báwo ni ìyanu rẹ̀ ṣe pọ̀ !

Ìjọba rẹ̀, ìjọba títí ayé ni;

ilẹ̀ ọba rẹ̀ láti ìran ìran ni.

Nítorí a ọmọ kan fún wa,

a fi ọmọkùnrin kan fún wa,

ìjọba yóò èjìká rẹ̀.

A ó máa é

Ìyanu Olùdámọ̀ràn, Ọlọ́run Alágbára,

Baba ayérayé, Ọmọ ọba aládé Àlàáfíà.

ti gbígbòòrò Ìjọba rẹ̀ àti àlàáfíà rẹ̀ ni yóò ìpẹ̀kun.

Yóò jẹ ọba lórí ìtẹ́ Dafidi

àti lórí ̀kún un rẹ̀ gbogbo,

nípa ìfìdímúlẹ̀ àti ìgbéró rẹ̀,

pẹ̀òtítọ́ àti òdodo

láti ìgbà náà lọ àti títí láéláé.

Ìtara Olúwa àwọn ọmọ-ogun

ni yóò èyí ṣẹ.Olúwa

Nítorí ó ti wa gbà kúrò nínú agbára òkùnkùn ó wa ìjọba Ọmọ ó fẹ́ràn. Nínú ẹni a ìràpadà, àti ìdáríjì ̀ṣẹ̀.

èyí ó fi sínú Kristi, nígbà o ti dìde kúrò nínú òkú, ó un jókòó lọ́wọ́ ̀tún nínú àwọn ̀run. Ó gbéga ju gbogbo ìjọba, àti àṣẹ, àti agbára, àti òye àti gbogbo orúkọ a ń , í ṣe ni ayé yìí nìkan, ṣùgbọ́n ni èyí ń bọ̀ pẹ̀.

Nítorí ìlú ìbílẹ̀ ń bẹ̀ ̀run, láti ibi ti àwa pẹ̀gbé ń fojúsọ́fún Olùgbàlà, Jesu Kristi Olúwa. Ẹni yóò sọ ara ìrẹ̀lẹ̀ wa di ̀tún ó ara ògo rẹ̀ mu, nípa agbára ó ó ṣe é ṣe fún un láti tẹ orí ohun gbogbo fún ara rẹ̀.

Nítorí àwa mọ̀ Kristi ti dìde kúrò nínú òkú. Òun mọ́. Ikú agbára lórí rẹ̀ mọ́.

Ìdí nìyìí àwọn ó lábẹ́ àkóso ara ̀ṣẹ̀, le è tẹ́ Ọlọ́run lọ́rùn.

Ṣùgbọ́n ẹyin nínú ti ara, ṣe nínú ti ̀, ó ṣe ̀Ọlọ́run ń gbé inú yín. Ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni ̀Kristi, òun nínú ẹni tirẹ̀.

Nítorí gbogbo ènìyàn ti nínú Adamu, bẹ́̀ a ó sọ gbogbo ènìyàn alààyè nínú Kristi. Ṣùgbọ́n olúkúlùkù ènìyàn ipá tirẹ̀: Kristi àkọ́; lẹ́yìn èyí àwọn ó jẹ́ Kristi ni wíwá rẹ̀. Nígbà náà ni òpin yóò , nígbà ó ti fi ìjọba fún Ọlọ́run Baba, nígbà ó pa gbogbo àṣẹ àti gbogbo ọlá àti agbára run. Nítorí ti òun gbọdọ̀ ti jẹ ọba òun to fi gbogbo àwọn ̀rẹ̀ abẹ́ ẹsẹ̀ rẹ̀.

"Ìjọba àti ̀ń bẹ lọ́dọ̀ Ọlọ́run rẹ̀,

òun i ṣe ìlàjà ibi gíga gíga ̀run.

Seja o primeiro