Pular para o conteúdo
Publicidade

Jó 25

Ìdáhùn Bilidadi

1 Nígbà náà Bilidadi, ará Ṣuhi, dáhùn ,

2 "Ìjọba àti ̀ń bẹ lọ́dọ̀ Ọlọ́run rẹ̀,

òun i ṣe ìlàjà ibi gíga gíga ̀run.

3 Àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ ha ìyè ,

tàbí ara ta ni ìmọ́lẹ̀ rẹ̀ tàn ?

4 Èéha ti ṣe a ó fi ènìyàn láre lọ́dọ̀ Ọlọ́run?

Tàbí ẹni a láti inú obìnrin yóò ha ṣe mọ́?

5 Kíyèsi i, òṣùpá tàn ìmọ́lẹ̀,

àní àwọn ìràwọ̀ mọ́lẹ̀ ojú rẹ̀,

6 a sọ ènìyàn i ṣe ìdin,

àti ọmọ ènìyàn í ṣe kòkòrò!"

Veja também