Pular para o conteúdo
Publicidade

Misericórdia

Por Bíblia Online

A misericórdia de Deus é eterna e inesgotável. Ele se compadece dos que sofrem, perdoa os arrependidos e derrama graça sobre os que não merecem. Grande é a sua fidelidade.

A misericórdia de Deus

Quem é Deus como tu, que perdoa a iniquidade? Ele se deleita em ter misericórdia e não retém a ira para sempre.

Ta ni Ọlọ́run rẹ̀,

ẹni ó dárí ̀ṣẹ̀ ,

ó fojú fo ìrékọjá èyí tókù ìní rẹ̀?

í dúró nínú ìbínú rẹ̀ láéláé

nítorí òun inú dídùn àánú.

Ṣàánú fún mi, Ọlọ́run,

gẹ́gẹ́ ìdúró ṣinṣin ìfẹ́ rẹ̀,

gẹ́gẹ́ ̀pọ̀ àánú rẹ̀

o pa gbogbo ̀ṣẹ̀ mi rẹ́.

Wẹ gbogbo àìṣedéédéé mi kúrò

o wẹ̀ mi mọ́ kúrò nínú ̀ṣẹ̀ mi!

Rántí, Olúwa àánú àti ìfẹ́ ̀ rẹ̀ ńlá,

torí wọ́n ti ìgbà àtijọ́.

ṣe rántí àwọn ̀ṣẹ̀ ìgbà èwe mi

tàbí ìrékọjá mi;

gẹ́gẹ́ i ìfẹ́ rẹ̀ rántí mi

nítorí ìwọ dára, Ìwọ! Olúwa.

Láti inú ibú ni

èmi ń é ́ Olúwa

Olúwa, gbóhùn mi,

jẹ́ etí rẹ o tẹ́ sílẹ̀ ohùn ̀bẹ̀ mi.

Ìwọ ṣe, fa àánú rẹ ó rọ́sẹ́yìn kúrò lọ́dọ̀ mi Olúwa;

jẹ́ ìṣeun ìfẹ́ rẹ àti òtítọ́ rẹ

ó máa pa mi mọ́ títí ayérayé.

Nítòótọ́, ìre àti àánú ni yóò máa tọ̀ lẹ́yìn

ọjọ́ ayé è mi gbogbo,

èmi yóò máa gbé inú ilé Olúwa

títí láéláé.

baba ti ń ṣe ìyọ́àwọn ọmọ rẹ̀,

bẹ́̀ ni Olúwa ń ṣe ìyọ́àwọn ó bẹ̀rẹ̀,

Graça e perdão

Onde o pecado abundou, superabundou a graça. Deus convida todos ao arrependimento e promete perdão total aos que confessam.

Ṣùgbọ́n ̀bùn ̀fẹ́ dàbí ̀ṣẹ̀. Nítorí nípa ̀ṣẹ̀. Nítorí o jẹ ẹnìkan ẹni púpọ̀ , mélòó mélòó ni oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run, àti ̀bùn nínú oore-ọ̀fẹ́ ọkùnrin kan, Jesu Kristi, di púpọ̀ fún ẹni púpọ̀.

Ẹrú ìṣòdodo

Ǹjẹ́ èyí túmọ̀ , nísinsin yìí, a tẹ̀síwájú láti máa dẹ́ṣẹ̀ láìbìkítà, nítorí ìgbàlà wa dúró nípa òfin mọ́, ṣe nípa gbígba oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run!

Ṣùgbọ́n Ọlọ́run, ẹni í ṣe ọlọ́rọ̀ ni àánú, nítorí ìfẹ́ ńlá rẹ̀ ó fi fẹ́ wa, nígbà àwa tilẹ̀ ti nítorí ìrékọjá wa, ó sọ di ààyè pẹ̀Kristi, oore-ọ̀fẹ́ ni a ti fi gbà yín .

Òun fún mi , "Oore-ọ̀fẹ́ mi fún , nítorí a sọ agbára mi di pípé nínú àìlera." Nítorí náà tayọ̀tayọ̀ ni èmi ó kúkú máa fi ṣògo nínú àìlera mi, agbára Kristi máa gbé inú mi.

Ẹni ó bo ̀ṣẹ̀ rẹ̀ mọ́lẹ̀ yóò ṣe rere,

ṣùgbọ́n ẹni ó jẹ́wọ́ ó kọ̀ wọ́n sílẹ̀ máa ń àánú gbà.

Jẹ́ ìkà ó kọ ̀rẹ̀ sílẹ̀

àti ènìyàn búburú èrò rẹ̀.

Jẹ́ ó yípadà Olúwa, Òun yóò ṣàánú fún un,

àti Ọlọ́run wa, nítorí Òun yóò dáríjì.

Síbẹ̀síbẹ̀ Olúwa fẹ́ síjú àánú ́;

ó dìde láti ṣàánú fún .

Nítorí Olúwa jẹ́ Ọlọ́run ìdájọ́.

Ìbùkún ni fún gbogbo àwọn ó dúró é!

Misericórdia e compaixão

Misericórdia quero e não sacrifício. Deus nos chama a ser misericordiosos como Ele é, perdoando e acolhendo o próximo.

Ṣùgbọ́n lọ kọ́ ohun ti èyí túmọ̀ : Àánú ni èmi ń fẹ́, í ṣe ẹbọ,nítorí èmi láti pe àwọn olódodo, ṣe àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀."

Òwe aláìláàánú ọmọ ̀dọ̀

Nígbà náà ni Peteru sọ́dọ̀ Jesu, ó béèrè , "Olúwa, nígbà mélòó ni arákùnrin mi yóò ṣẹ̀ mi, èmi yóò dáríjì í? Tàbí ìgbà méje ni?"

Jesu dáhùn , "Mo fún , í ṣe ìgbà méje, ṣùgbọ́n ìgbà àádọ́rin méje.

Nítorí náà, ̀yin dárí àwọn ṣẹ̀ yín, baba yín ̀run náà yóò dáríjì yín.

Ṣùgbọ́n nínú ̀pọ̀ àánú rẹ, ìwọ òpin wọn tàbí kọ̀ wọ́n sílẹ̀, nítorí ìwọ ni Ọlọ́run olóore-ọ̀fẹ́ àti aláàánú.

Ènìyàn rere fi ojúrere hàn,

a wínni;

ìmòye ni yóò máa fi la ̀iṣẹ́ rẹ̀.

Jẹ́ ẹwà Olúwa Ọlọ́run wa lára wa;

fi ìdí iṣẹ́ ọwọ́ wa múlẹ̀ lára wa,

bẹ́̀ ni, ó fi ìdí iṣẹ́ ọwọ́ wa múlẹ̀.

Acessar a misericórdia

Cheguemos com confiança ao trono da graça. Ali encontramos misericórdia e graça para socorro no tempo oportuno.

Nítorí náà, jẹ́ a si ibi ìtẹ́ oore-ọ̀fẹ́ pẹ̀ìgboyà, a àánú gbà, a oore-ọ̀fẹ́ láti máa ran ni lọ́wọ́ àkókò ó wọ̀.

Ẹbọ ààyè mímọ́

Nítorí náà mo fi ìyọ́Ọlọ́run bẹ̀ yín ará, ̀yin ó fi ara yín fún Ọlọ́run ẹbọ ààyè mímọ́, ìtẹ́wọ́gbà, èyí ni iṣẹ́ ìsìn yín ó tọ̀.

"Nítorí Ọlọ́run fẹ́ aráyé bẹ́̀ gẹ́́, ó fi ọmọ rẹ̀ kan ṣoṣo fún ni, ẹnikẹ́ni ó gbà á gbọ́, á ṣègbé, ṣùgbọ́n ó ìyè àìnípẹ̀kun.

Nítorí a ti fún yin ni àǹfààní, í ṣe láti gba Kristi gbọ́ nìkan, ṣùgbọ́n láti jìyà nítorí rẹ̀ pẹ̀.

Hesekiah ṣe àsè ìrékọjá

Hesekiah ránṣẹ́ gbogbo Israẹli àti Juda, ó kọ ìwé Efraimu àti Manase, wọn ó sínú ilé Olúwa Jerusalẹmu láti pa àjọ ìrékọjá mọ́ Olúwa Ọlọ́run Israẹli. Nítorí ọba ti gbìmọ̀ àti àwọn ìjòyè rẹ̀, àti gbogbo ìjọ ènìyàn Jerusalẹmu, láti pa àjọ ìrékọjá mọ́ oṣù kejì. Nítorí wọn pa á mọ́ àkókò náà, nítorí àwọn àlùfáà i ya ara wọn mímọ́ ; bẹ́̀ ni àwọn ènìyàn ì ara wọn jọ Jerusalẹmu. ̀rọ̀ náà tọ́ lójú ọba àti lójú gbogbo ìjọ ènìyàn. Bẹ́̀ ni wọ́n fi àṣẹ kan lélẹ̀, láti kéde gbogbo Israẹli láti Beerṣeba àní títí Dani, láti pa àjọ ìrékọjá mọ́ Olúwa Ọlọ́run Israẹli Jerusalẹmu: nítorí wọn pa á mọ́ ọjọ́ púpọ̀ gẹ́gẹ́ a ti kọ ́.

Bẹ́̀ àwọn oníṣẹ́ ń sáré lọ pẹ̀ìwé láti ọwọ́ ọba àti àwọn ìjòyè rẹ̀ gbogbo Israẹli àti Juda; àti gẹ́gẹ́ àṣẹ ọba, ,

"̀yin ọmọ Israẹli padà Olúwa Ọlọ́run Abrahamu, Isaaki, àti Israẹli, òun ó yípadà àwọn ìyókù nínú yín, ó sálà kúrò lọ́wọ́ àwọn ọba Asiria. ̀yin ó ṣe dàbí àwọn baba yín, àti àwọn arákùnrin yín ó dẹ́ṣẹ̀ Olúwa, Ọlọ́run àwọn baba wọn, nítorí náà ó ṣe fi wọ́n fún ìdahoro ̀yin ti . Ǹjẹ́ ̀yin ó ṣe ṣe ọlọ́rùn líle, àwọn baba yín, ṣùgbọ́n jọ̀wọ́ ara yín lọ́wọ́ fún Olúwa, wọ inú ibi mímọ́ rẹ̀ lọ, ti òun ti ìyàsímímọ́ títí láé. sin Olúwa, Ọlọ́run yín gbígbóná ìbínú rẹ̀ ó yípadà kúrò ̀dọ̀ yín. Nítorí ̀yin tún yípadà Olúwa, àwọn arákùnrin yín, àti àwọn ọmọ yín, yóò àánú níwájú àwọn ó wọn ìgbèkùn lọ, wọn ó tún padà ilẹ̀ : nítorí Olúwa Ọlọ́run yín, oníyọnu àti aláàánú ni, yóò ojú rẹ̀ padà kúrò lọ́dọ̀ yín, ̀yin padà sọ́dọ̀ rẹ̀."

Bẹ́̀ ni àwọn oníṣẹ́ náà kọjá láti ìlú ìlú, ilẹ̀ Efraimu àti Manase títí Sebuluni, ṣùgbọ́n wọ́n fi wọ́n rẹ́rìn-ín ẹlẹ́, wọ́n gàn wọ́n. Síbẹ̀ òmíràn nínú àwọn ènìyàn Aṣeri àti Manase àti Sebuluni rẹ̀ ara wọn sílẹ̀, wọ́n Jerusalẹmu. Juda pẹ̀, ọwọ́ Ọlọ́run láti fún wọn ọkàn kan láti pa òfin ọba mọ́ àti àwọn ìjòyè, nípa ̀rọ̀ Olúwa.

̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn péjọ Jerusalẹmu, láti pa àjọ àkàrà àìwú mọ́ oṣù kejì. Wọ́n dìde, wọ́n gbogbo pẹpẹ ó Jerusalẹmu lọ, àti gbogbo pẹpẹ tùràrí ni wọ́n lọ, wọ́n wọ́n odò Kidironi.

Nígbà náà ni wọ́n pa ẹran ìrékọjá náà ọjọ́ kẹrìnlá oṣù kejì: ojú ti àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi, wọ́n ara wọn mímọ́, wọ́n ẹbọ sísun sínú ilé Olúwa. Wọ́n dúró ipò wọn, ètò wọn gẹ́gẹ́ òfin Mose, ènìyàn Ọlọ́run: àwọn àlùfáà wọ́n ̀jẹ̀ náà, wọ́n gbà lọ́wọ́ àwọn ọmọ Lefi. Nítorí ̀pọ̀lọpọ̀ ni ó nínú ìjọ ènìyàn náà ara wọn mímọ́: nítorí náà ni àwọn ọmọ Lefi ṣe ń tọ́àti pa ẹran ìrékọjá fún olúkúlùkù ẹni ó ṣe aláìmọ́, láti á mímọ́ Olúwa. ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn, àní ̀pọ̀lọpọ̀ nínú Efraimu àti Manase, Isakari, àti Sebuluni wẹ̀ ara wọn mọ́ síbẹ̀ wọ́n jẹ ìrékọjá náà, í ṣe gẹ́gẹ́ a ti kọ ́. Ṣùgbọ́n Hesekiah bẹ̀bẹ̀ fún wọn, , Olúwa, ẹni rere, dáríjì olúkúlùkù, ó múra ọkàn rẹ̀ láti Ọlọ́run, Olúwa Ọlọ́run àwọn baba rẹ̀ ṣùgbọ́n í ṣe nípa ìwẹ̀nùmọ́ mímọ́ Olúwa gbọ́ ti Hesekiah, ó àwọn ènìyàn náà láradá.

Àwọn ọmọ Israẹli a Jerusalẹmu fi ayọ̀ ńlá pa àjọ àkàrà àìwú mọ́ ọjọ́ méje: àwọn ọmọ Lefi, àti àwọn àlùfáà yin Olúwa lójoojúmọ́, wọ́n ń fi ohun èlò olóhùn gooro kọrin Olúwa.

Hesekiah sọ̀rọ̀ ìtùnú fún gbogbo àwọn ọmọ Lefi, ó lóye ìmọ̀ rere Olúwa: ọjọ́ méje ni wọ́n fi jẹ àsè náà wọ́n ẹbọ àlàáfíà, wọ́n ń fi ohùn rara dúpẹ́ fún Olúwa, Ọlọ́run àwọn baba wọn.

Gbogbo ìjọ náà gbìmọ̀ láti pa ọjọ́ méje mìíràn mọ́: wọ́n fi ayọ̀ pa ọjọ́ méje mìíràn mọ́. Nítorí Hesekiah, ọba Juda, ta ìjọ ènìyàn náà ọrẹ, ẹgbẹ̀rún (1,000) akọ màlúù, àti ̀́dẹ́gbàárin (7,000) àgùntàn. ̀pọ̀lọpọ̀ nínú àwọn àlùfáà ya ara wọn mímọ́. Gbogbo ìjọ ènìyàn Juda pẹ̀àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi, àti gbogbo ìjọ ènìyàn ó ti inú Israẹli jáde , àti àwọn àjèjì ó ti ilẹ̀ Israẹli jáde , àti àwọn ń gbé Juda yọ̀. Bẹ́̀ ni ayọ̀ ńlá Jerusalẹmu: nítorí láti ọjọ́ Solomoni, ọmọ Dafidi, ọba Israẹli, irú èyí Jerusalẹmu. Nígbà náà ni àwọn àlùfáà, àwọn ọmọ Lefi dìde, wọ́n súre fún àwọn ènìyàn náà: a gbọ́ ohùn wọn, àdúrà wọn gòkè lọ si ibùgbé mímọ́ rẹ̀, àní ̀run.

"ọkùnrin kan kọ ìyàwó rẹ̀ sílẹ̀

obìnrin náà lọ fẹ́ ọkọ mìíràn,

ǹjẹ́ ọkùnrin náà tún tọ̀ ́ ?

Ǹjẹ́ ilẹ̀ náà di aláìmọ́ ?

Ṣùgbọ́n ìwọ ti gbé pẹ̀onírúurú panṣágà gẹ́gẹ́ olùfẹ́,

ṣé ìwọ yóò tún padà sọ́dọ̀ mi ?"

ni Olúwa .

"Gbé ojú rẹ sókè ibi gíga wọ̀n-ọn-nì,

o ó ibi kan ha a ́ jẹ́?

ojú ̀, ìwọ jókòó de àwọn olólùfẹ́,

i ará Arabia kan nínú aginjù,

ìwọ ti ba ilẹ̀ náà jẹ́

pẹ̀ìwà àgbèrè àti ìwà búburú rẹ.

Nítorí náà, a ti fa ̀wààrà òjò sẹ́yìn,

ṣí òjò àrọ̀kúrò.

Síbẹ̀ ìwọ ojú líle ti panṣágà,

ìwọ kọ̀ láti ìtìjú.

Ǹjẹ́ ìwọ ha a láìpẹ́ yìí ,

Baba mi, ìwọ ̀rẹ́ mi láti ìgbà èwe mi.

Ìwọ yóò ha máa bínú títí?

Ìbínú rẹ yóò ha máa lọ títí láé?

Báyìí ni o ṣe ń sọ̀rọ̀

ìwọ ṣe gbogbo ibi ìwọ le ṣe."

Israẹli aláìṣòótọ́

àkókò ìjọba Josiah ọba, Olúwa fún mi , "Ṣé o ti nǹkan àwọn Israẹli aláìnígbàgbọ́ ti ṣe? Wọ́n ti lọ àwọn òkè gíga àti abẹ́ àwọn igi, wọ́n ti ṣe àgbèrè níbẹ̀. Mo nígbà wọ́n ti ṣe èyí wọn yóò padà, wọn padà, Juda aláìgbàgbọ́ arábìnrin rẹ̀ náà i. Mo fún Israẹli aláìnígbàgbọ́ ìwé ìkọ̀sílẹ̀, mo wọn kúrò nítorí gbogbo àgbèrè wọn. Síbẹ̀ mo Juda ó jẹ́ arábìnrin rẹ̀ bẹ̀, òun náà jáde lọ láti lọ ṣe àgbèrè. Nítorí ìwà èérí Israẹli jọ ́ lójú, ó ti ba ilẹ̀ jẹ́, ó ti ṣe àgbèrè pẹ̀òkúta àti igi. Látàrí gbogbo nǹkan wọ̀nyí Juda arábìnrin rẹ̀ aláìgbàgbọ́ padà tọ̀ pẹ̀gbogbo ọkàn rẹ̀, ṣe nípa fífarahàn olóòtítọ́," ni Olúwa .

Olúwa fún mi , "Israẹli aláìnígbàgbọ́ ṣe òdodo ju Juda ó ìgbàgbọ́ lọ. Lọ polongo ̀rọ̀ náà, lọ ìhà àríwá:

" Yípadà, Israẹli aláìnígbàgbọ́,’ ni Olúwa .

Ojú mi yóò korò mọ́,

nítorí mo jẹ́ aláàánú, ni Olúwa .

Èmi yóò bínú mọ́ títí láé.

à ti mọ ̀bi rẹ,

ìwọ ti ṣọ̀tẹ̀ Olúwa Ọlọ́run rẹ,

ìwọ ti ojúrere rẹ lọ́dọ̀ ọlọ́run àjèjì

lábẹ́ gbogbo igikígi ó gbilẹ̀,

̀yin gba ohun mi gbọ́,’ "

ni Olúwa .

"Padà, ̀yin ènìyàn aláìnígbàgbọ́," ni Olúwa , "nítorí èmi ni ọkọ rẹ. Èmi ó yàn ́, ̀kan láti ìlú àti méjì láti ̀. Èmi ó Sioni. Lẹ́yìn èyí, èmi ó fún àwọn olùṣọ́-àgùntàn láti inú ọkàn mi, wọn yóò ṣáájú yín pẹ̀òye àti ìmọ̀. ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì, ̀yin pọ̀ i lórí ilẹ̀ náà," ni Olúwa , "àwọn ènìyàn tún sọ , Àpótí ̀Olúwa.ìrántí wọn mọ́, a yóò pàdánù rẹ̀, bẹ́̀ ni a yóò tún kan òmíràn mọ́. ìgbà náà, wọn yóò pe Jerusalẹmu ìtẹ́ Olúwa gbogbo orílẹ̀-èdè yóò péjọ Jerusalẹmu láti bọ̀wọ̀ fún orúkọ Olúwa, wọn yóò tún tẹ̀àyà líle búburú wọn mọ́. ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì ni ilé Juda yóò darapọ̀ mọ́ ilé Israẹli. Wọn yóò láti ilẹ̀ àríwá ilẹ̀ mo fi fún àwọn baba ńlá yín gẹ́gẹ́ ilẹ̀ ìní.

"Èmi fúnra mi sọ ,

" Báwo ni inú mi yóò ti dùn ,

èmi ó tọ́ ọmọkùnrin

n fún ilẹ̀ ó .

Mo ìwọ yóò Baba mi

o ṣàì tọ̀ lẹ́yìn.

Ṣùgbọ́n gẹ́gẹ́ aláìgbàgbọ́ obìnrin ọkọ rẹ̀,

bẹ́̀ gẹ́gẹ́ o jẹ́ aláìgbàgbọ́ mi. Ìwọ ilé Israẹli,"

ni Olúwa .

A gbọ́ ohùn àgàn láti ibi gíga,

ẹkún àti ̀bẹ̀ àwọn ọmọ Israẹli,

nítorí wọ́n ti ̀wọn po,

wọ́n ti gbàgbé Olúwa Ọlọ́run wọn.

"Padà, ̀yin ènìyàn aláìnígbàgbọ́,

Èmi ó wo ìpadàsẹ́yìn kúrò ̀títọ́ rẹ sàn."

"Bẹ́̀, ni a ó sọ́dọ̀ rẹ

nítorí ìwọ ni Olúwa Ọlọ́run wa.

Nítòótọ́, asán ni ìbọ̀rìṣà àti ìrúkèrúdò ó àwọn orí òkè

kéékèèké àti àwọn òkè gíga,

nítòótọ́, nínú Olúwa Ọlọ́run

wa ni ìgbàlà Israẹli .

Láti ìgbà èwe wa ni àwọn òrìṣà ìtìjú ti

jẹ èso iṣẹ́ àwọn baba wa run,

̀wọ́ ẹran wọn àti agbo ẹran wọn,

ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin wọn.

Jẹ́ a dùbúlẹ̀ nínú ìtìjú wa,

ìtìjú wa mọ́lẹ̀.

A ti ṣẹ̀ Olúwa Ọlọ́run wa,

àwa àti àwọn baba wa,

láti ìgbà èwe wa títí di òní

a gbọ́rọ̀ Olúwa Ọlọ́run wa."

Seja o primeiro

Este artigo te tocou? Faça uma oração!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.