Pular para o conteúdo
Publicidade

Pais e filhos

Por Bíblia Online

A relação entre pais e filhos é uma das mais preciosas na Bíblia. Deus estabeleceu a família como escola de fé, amor e formação de caráter.

Honrar pai e mãe

Honrar os pais é o primeiro mandamento com promessa. Os filhos são chamados a obedecer, respeitar e cuidar de seus pais.

Bọ̀wọ̀ fún baba òun ìyá rẹ, ọjọ́ rẹ ó pẹ́ orí ilẹ̀ Olúwa Ọlọ́run rẹ fi fún .

Àwọn ọmọ àti àwọn òbí

̀yin ọmọ, máa gbọ́ àwọn òbí i yín nínú Olúwa, nítorí èyí ó tọ́. "Bọ̀wọ̀ fún baba àti ìyá rẹ," èyí í ṣe òfin kìn-ín-ní pẹ̀ìlérí, "ki ó dára fún , àti ìwọ pẹ́ ayé."

̀yin ọmọ máa gbọ́ ti àwọn òbí yín ohun gbogbo, nítorí èyí dára gidigidi nínú Olúwa.

Fetí ti baba rẹ ó ,

ṣe gan ìyá rẹ, nígbà o gbó.

Ẹni ó ṣìkà baba rẹ̀, ó ìyá rẹ̀ jáde

òun ni ọmọ ń ṣe ìtìjú, ó ̀gàn .

ènìyàn kan ṣépè fún baba tàbí ìyá rẹ̀,

ìmọ́lẹ̀ rẹ̀ ni a ó pa nínú òkùnkùn biribiri.

Ṣùgbọ́n opó kan ni ọmọ tàbí ọmọ ọmọ, jẹ́ wọn kọ́kọ́ kọ́ a ti ń ṣe ìtọ́ilé àwọn tìkára wọn, wọn san oore àwọn òbí wọn padà; nítorí èyí ni ó ṣe ìtẹ́wọ́gbà níwájú Ọlọ́run.

Instruir os filhos

Os pais devem instruir os filhos no caminho certo. A educação começa cedo, com disciplina amorosa e ensino constante da Palavra.

Tọ́ ọmọdé ̀yóò tọ̀:

nígbà ó dàgbà, yóò kúrò nínú rẹ̀.

Àwọn àṣẹ mo fún un yín lónìí gbọdọ̀ máa lóókan àyà yín. fi kọ́ àwọn ọmọ yín gidigidi. jókòó nínú ilé, jíròrò nípa wọn, àti nígbà ń rìn ojú ̀, dùbúlẹ̀ àti nígbà dìde.

̀rọ̀ ìyànjú láti ṣàfẹ́ọgbọ́n

Tẹ́, ìwọ ọmọ mi ̀kọ́ baba rẹ,

ṣe kọ ̀kọ́ màmá rẹ sílẹ̀.

Wọn yóò jẹ́ òdòdó ̀yẹ olóòórùn dídùn lórí rẹ

àti ̀ṣọ́ ó dára ọrùn rẹ .

Àti ̀yin baba, ṣe àwọn ọmọ yín bínú, ṣùgbọ́n máa tọ́ wọn nínú ̀kọ́ àti ìkìlọ̀ Olúwa.

̀yin baba, ṣe àwọn ọmọ yín bínú, wọn á rẹ̀wẹ̀.

̀ìbániwí ń fún ni ọgbọ́n

ṣùgbọ́n ọmọ a fi sílẹ̀ fúnra rẹ̀ a dójútì ìyá rẹ̀.

Ẹni ó fa ọwọ́ ìbáwí sẹ́yìn kórìíra ọmọ rẹ̀

ṣùgbọ́n ẹni ó fẹ́ràn ọmọ rẹ̀ yóò máa a .

máa sùúrù lábẹ́ ìbáwí, Ọlọ́run wa ọmọ ni; nítorí ọmọ wo ni ń bẹ ti baba í ?

Filhos como bênção

Os filhos são herança do Senhor. A coroa dos velhos são os filhos dos filhos, e a glória dos filhos são seus pais.

Kíyèsi i, àwọn ọmọ ni ìní Olúwa:

ọmọ inú ni èrè rẹ̀.

ọfà ti ọwọ́ alágbára,

bẹ́̀ ni àwọn ọmọ èwe.

Ìbùkún ni fún ọkùnrin náà apó rẹ̀ kún fún wọn;

ojú yóò wọ́n,

ṣùgbọ́n wọn yóò ṣẹ́gun àwọn ̀ẹnu-ọ̀.

Ọmọ ọmọ ni adé orí arúgbó,

ògo àwọn ọmọ ni òbí jẹ.

Baba olódodo ni yóò yọ̀ gidigidi:

ẹni ó ọmọ ọlọ́gbọ́n,

yóò ayọ̀ nínú rẹ̀.

Àwọn òwe Solomoni.

Ọlọ́gbọ́n ọmọ ń inú baba rẹ̀ dùn,

ṣùgbọ́n aṣiwèrè ọmọ ń ba inú ìyá rẹ̀ jẹ́.

"Ta ni baba nínú yín ọmọ rẹ̀ yóò béèrè àkàrà lọ́dọ̀ rẹ̀, yóò fún un òkúta? Tàbí ó béèrè ẹja, yóò fún un ejò? Tàbí ó béèrè ̀yin, yóò fún un àkéekèe? Ǹjẹ́ ̀yin ó jẹ́ ènìyàn búburú mọ a ti í fi ̀bùn dáradára fún àwọn ọmọ yín, mélòó mélòó ha ni Baba yín ń bẹ ̀run yóò fi ̀Mímọ́ rẹ̀ fún àwọn ó béèrè lọ́dọ̀ rẹ̀!"

Ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni pèsè fún àwọn tirẹ̀, pàápàá fún àwọn ará ilé rẹ̀, ó ti sẹ́ ìgbàgbọ́, ó burú ju aláìgbàgbọ́ lọ.

Ṣùgbọ́n ̀yin fẹ́ láti sin Olúwa, nígbà náà yàn fún ara yín òní ẹni ̀yin yóò sìn bóyá òrìṣà àwọn baba ńlá yín sìn ìkọjá odò Eufurate, tàbí òrìṣà àwọn ará Amori, ilẹ̀ ẹni ̀yin ń gbé. Ṣùgbọ́n ti èmi àti ilé mi, Olúwa ni àwa yóò máa sìn."

Nítorí ìdí èyí, ọkùnrin yóò fi baba àti ìyá rẹ̀ sílẹ̀, yóò dàpọ̀ mọ́ aya rẹ̀, wọn yóò di ara kan.

Baba gbọdọ̀ fún àwọn ọmọ wọn tàbí àwọn ọmọ fún baba wọ́n; olúkúlùkù láti fún ̀ṣẹ̀ òun tìkára rẹ̀.

Seja o primeiro