Publicidade

Salmos 127

Orin fún ìgòkè. Ti Solomoni.

1 ṣe Olúwa kọ́ ilé náà

àwọn ń kọ́ ń ṣiṣẹ́ lásán ni;

ṣe Olúwa pa ìlú mọ́, olùṣọ́ lásán.

2 Asán ni fún ̀yin ti dìde kùtùkùtù

láti pẹ́ dùbúlẹ̀, láti jẹ oúnjẹ làálàá;

bẹ́̀ ni ó ń fi ìre fún olùfẹ́ rẹ̀ lójú ̀run.

3 Kíyèsi i, àwọn ọmọ ni ìní Olúwa:

ọmọ inú ni èrè rẹ̀.

4 ọfà ti ọwọ́ alágbára,

bẹ́̀ ni àwọn ọmọ èwe.

5 Ìbùkún ni fún ọkùnrin náà apó rẹ̀ kún fún wọn;

ojú yóò wọ́n,

ṣùgbọ́n wọn yóò ṣẹ́gun àwọn ̀ẹnu-ọ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-