Publicidade

Provérbios 23

Ìfẹ́kúfẹ̀́ ohun àdídùn

1 Nígbà ìwọ jókòó láti ìjòyè jẹun,

kíyèsi ohun ó níwájú rẹ gidigidi.

2 Ìwọ a fi ̀bẹ ara rẹ ̀fun,

ìwọ jẹ́ òkúndùn ènìyàn.

3 ṣe fẹ́ oúnjẹ dídùn rẹ̀:

nítorí oúnjẹ ̀tàn ni.

4 ṣe ṣe làálàá láti lọ́rọ̀:

ṣíwọ́ kúrò nínú ọgbọ́n ara rẹ.

5 Ìwọ ó ha fi ojú rẹ lépa ohun ?

Nítorí ̀rọ̀ hu ìyẹ́ apá fún ara rẹ̀,

ó ń idì ojú ̀run.

6 ṣe jẹ oúnjẹ ẹni ó háwọ́,

bẹ́̀ ni o ṣe fẹ́ oúnjẹ dídùn rẹ̀.

7 Nítorí ẹni ń ṣírò ọkàn rẹ̀, bẹ́̀ ni ó :

"Máa jẹ, o máa mu," ni ó ń fún ;

ṣùgbọ́n ọkàn rẹ̀ pẹ̀rẹ.

8 Òkèlè ìwọ jẹ ni ìwọ ó pọ̀ jáde,

ìwọ a sọ ̀rọ̀ dídùn rẹ̀ .

9 ṣe sọ̀rọ̀ etí aṣiwèrè;

nítorí yóò gan ọgbọ́n ̀rọ̀ rẹ.

10 ṣe ṣí ààlà àtijọ́ kúrò;

ṣe bọ́ sínú oko aláìní baba.

11 Nítorí Olùràpadà wọn lágbára;

yóò gba ìjà wọn .

12 Fi àyà ̀kọ́,

àti etí rẹ ̀rọ̀-ìmọ̀.

13 ṣe fa ọwọ́ ìbáwí sẹ́yìn kúrò lára ọmọdé,

nítorí ìwọ fi pàṣán án, òun yóò .

14 ìwọ fi pàṣán án,

ìwọ ó gbà ọkàn rẹ̀ kúrò ̀run àpáàdì.

̀rọ̀ ọgbọ́n fún ọmọ rere

15 Ọmọ mi, ọkàn rẹ gbọ́n,

ọkàn mi yóò yọ̀, àní èmi pẹ̀.

16 Inú mi yóò dùn nígbà ètè rẹ̀ ń sọ̀rọ̀ títọ́.

17 ṣe jẹ́ àyà rẹ ó ṣe ìlara àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀,

ṣùgbọ́n ìwọ ó ìbẹ̀Olúwa,

ọjọ́ gbogbo.

18 Nítorí ìgbẹ̀yìn ń bẹ nítòótọ́;

ìrètí rẹ̀ yóò kúrò.

19 Gbọ́, ìwọ ọmọ mi, o gbọ́n,

o máa tọ́ àyà rẹ ̀títọ́.

20 ṣe nínú àwọn ̀mùtí;

àti àwọn wọ̀bìà alájẹkì ̀jẹun;

21 nítorí ̀mùtí àti ̀jẹun ni yóò di tálákà;

ìmúni-tòògbé ń fi àkísà wọ ọkùnrin láṣọ.

22 Fetí ti baba rẹ ó ,

ṣe gan ìyá rẹ, nígbà o gbó.

23 Ra òtítọ́, o ṣe á;

ra ọgbọ́n pẹ̀àti ̀kọ́ àti òye.

24 Baba olódodo ni yóò yọ̀ gidigidi:

ẹni ó ọmọ ọlọ́gbọ́n,

yóò ayọ̀ nínú rẹ̀.

25 Jẹ́ baba rẹ àti ìyá rẹ ó yọ̀,

jẹ́ inú ẹni ó dùn.

26 Ọmọ mi, fi àyà rẹ fún mi,

o jẹ́ ojú rẹ inú dídùn ̀mi.

27 Nítorí panṣágà obìnrin ̀gbun jíjìn ni;

àti àjèjì obìnrin kànga híhá ni.

28 Òun á ba bùba olè,

a sọ àwọn olùrékọjá di púpọ̀ nínú àwọn ènìyàn.

29 Ta ni ó ni òsì? Ta ni ó ni ìbànújẹ́?

Ta ni ó ni ìjà? Ta ni ó ni asọ̀? Ta ni ó ni ọgbẹ́ láìnídìí?

30 Àwọn ó dúró pẹ́ níbi ọtí wáìnì;

àwọn ń lọ láti dán ọtí wáìnì àdàlú .

31 Ìwọ ṣe ọtí wáìnì nígbà ó pọ́n,

nígbà ó ń fi àwọ̀ rẹ̀ hàn nínú ago,

a gbé e , ó ń dùn.

32 Níkẹyìn òun á bu ni ṣán ejò,

a bunijẹ i paramọ́lẹ̀.

33 Ojú rẹ yóò àwọn àjèjì obìnrin,

àyà rẹ yóò sọ̀rọ̀ àyídáyidà.

34 Nítòótọ́, ìwọ ó dàbí ẹni ó dùbúlẹ̀ àárín Òkun,

tàbí ẹni ó dùbúlẹ̀ lókè-ọkọ̀.

35 Ìwọ ó , "Wọ́n ; dùn ;

wọ́n , èmi mọ̀:

nígbà wo ni èmi ó ?

Èmi ó tún máa òmíràn láti mu."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-