Publicidade

Provérbios 29

1 Ẹni ó ń ṣorí kunkun lẹ́yìn ̀pọ̀lọpọ̀ ìbáwí

yóò parun lójijì láìsí àtúnṣe.

2 Nígbà olódodo ń gbilẹ̀, àwọn ènìyàn a yọ̀

nígbà ènìyàn búburú ń ṣàkóso, àwọn ènìyàn ń kórìíra.

3 Ènìyàn ó fẹ́ràn ọgbọ́n baba rẹ̀ láyọ̀

ṣùgbọ́n ẹni ti ń panṣágà kẹ́gbẹ́ ba ọrọ̀ rẹ̀ jẹ́.

4 Nípa ìdájọ́ òdodo ni ọba fi í ìlú tòrò nini,

ṣùgbọ́n èyí ń ṣe ojúkòkòrò àbẹ̀tẹ́lẹ̀ á lulẹ̀.

5 Ẹnikẹ́ni ó tan aládùúgbò rẹ̀

ó ń dẹ àwọ̀n de ẹsẹ̀ rẹ̀.

6 ̀ṣẹ̀ ènìyàn ibi ni ó jẹ́ ìdẹ̀kùn rẹ̀

ṣùgbọ́n olódodo le è kọrin ó máa yọ̀.

7 Olódodo ń máa ro ̀rọ̀ tálákà,

ṣùgbọ́n ènìyàn búburú i láti ó.

8 Àwọn ẹlẹ́a máa ru ìlú sókè,

ṣùgbọ́n àwọn ọlọ́gbọ́n ènìyàn máa ń ìbínú kúrò.

9 ọlọ́gbọ́n ènìyàn lọ ilé ẹjọ́ pẹ̀aláìgbọ́n

aláìgbọ́n a máa bínú a máa , àlàáfíà.

10 Àwọn ó ń tàjẹ̀ sílẹ̀ ẹni dídúró ṣinṣin

wọ́n ń ̀láti pa olódodo.

11 Aláìgbọ́n ènìyàn fi gbogbo ẹnu rẹ̀ bínú

ṣùgbọ́n ọlọ́gbọ́n ènìyàn a máa ìbínú rẹ̀ ìjánu.

12 olórí fetí irọ́,

gbogbo àwọn ìjòyè rẹ̀ a di ènìyàn búburú lójú rẹ̀.

13 Tálákà ènìyàn àti aninilára jọ àbùdá yìí,

Olúwa jẹ́ ojú àwọn méjèèjì máa ríran.

14 ọba kan ń ṣe ìdájọ́ tálákà pẹ̀òtítọ́

ìtẹ́ ìjọba rẹ yóò fìdímúlẹ̀ nígbà gbogbo.

15 ̀ìbániwí ń fún ni ọgbọ́n

ṣùgbọ́n ọmọ a fi sílẹ̀ fúnra rẹ̀ a dójútì ìyá rẹ̀.

16 Nígbà ènìyàn búburú ń gbilẹ̀, bẹ́̀ náà ni ̀ṣẹ̀ ń gbilẹ̀

ṣùgbọ́n olódodo yóò ìṣubú wọn.

17 ọmọ rẹ , yóò fún àlàáfíà

yóò inú dídùn inú ọkàn rẹ.

18 Níbi ti ìfihàn, àwọn ènìyàn a gbé ìgbé ayé àìbìkítà,

ṣùgbọ́n ìbùkún fún àwọn ń pa òfin mọ́.

19 A le fi ̀rọ̀ lásán kìlọ̀ fún ìránṣẹ́

ó tilẹ̀ e, kọbi ara i.

20 Ǹjẹ́ ó ènìyàn ń kánjú sọ̀rọ̀?

Ìrètí fún aláìgbọ́n ú lọ.

21 ènìyàn kan kẹ́ ìránṣẹ́ rẹ̀ lákẹ̀́láti kékeré

yóò ìbànújẹ́ ìgbẹ̀yìn.

22 Oníbìínú ènìyàn a ru ìjà sókè,

onínú-fùfù ènìyàn a máa ̀pọ̀lọpọ̀ ̀ṣẹ̀.

23 Ìgbéraga ènìyàn a máa sọ ́ di ẹni ilẹ̀

ṣùgbọ́n onírẹ̀lẹ̀ ènìyàn a máa gba iyì kún iyì.

24 Ẹni ó ń ẹgbẹ́, olè kórìíra ọkàn ara rẹ̀,

ó ń gbọ́ èpè olóhun le è fọhùn.

25 Ìbẹ̀ènìyàn kan yóò di ìdẹ̀kùn

ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni ó bẹ̀Olúwa láìléwu.

26 ̀pọ̀lọpọ̀ ni ń ojúrere alákòóso,

ṣùgbọ́n láti ̀dọ̀ Olúwa ni ènìyàn ń gba ìdájọ́ òdodo.

27 Olódodo kórìíra àwọn aláìṣòótọ́:

ènìyàn búburú kórìíra olódodo.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-