Pular para o conteúdo
Publicidade

Proximidade

Por Bíblia Online

Deus é próximo dos que o buscam. Ele não é um Deus distante, mas presente, íntimo e acessível a todo o que o invoca com sinceridade de coração.

Buscar a presença de Deus

A Bíblia nos exorta a buscar a face do Senhor continuamente. Quem se aproxima dele encontra plenitude de alegria e delícias perpétuas.

Olúwa àti ipá rẹ̀;

wa ojú rẹ̀ nígbà gbogbo.

Olúwa àti agbára rẹ̀;

e ojú rẹ̀ nígbà gbogbo.

Olúwa nígbà i;

é nígbà ó nítòsí.

Ohun kan ni mo béèrè lọ́dọ̀ Olúwa,

òhun ni èmi yóò máa kiri:

èmi ó le ilé Olúwa

ọjọ́ ayé mi gbogbo,

èmi: ó le kíyèsi ẹwà Olúwa,

èmi ó máa tẹmpili rẹ̀.

Dídára ọjọ́ kan ààfin rẹ

ju ẹgbẹ̀rún (1,000) ọjọ́ lọ;

èmi o kúkú máa ṣe aṣọ́nínú ilé Ọlọ́run mi

láti gbé àgọ́ àwọn ènìyàn búburú.

Ìwọ ti fi ipa ̀ìyè hàn ;

Ìwọ yóò kún mi pẹ̀ayọ̀ iwájú rẹ,

pẹ̀ìdùnnú ayérayé ọwọ́ ̀tún rẹ.

Deus está perto

O Senhor está perto dos que o invocam, dos quebrantados de coração e dos que clamam por socorro. Sua presença nos sustenta.

Nígbà olódodo fún ìrànlọ́wọ́,

Olúwa a máa gbọ́, a yọ wọ́n jáde láti inú gbogbo wàhálà wọn.

Olúwa súnmọ́ etí ̀dọ̀ àwọn oníròbìnújẹ́ ọkàn;

ó gba irú àwọn í ṣe oníròra ọkàn .

jẹ́ ki ìpamọ́ra yín di mímọ́ fún gbogbo ènìyàn, Olúwa ń bẹ nítòsí.

Ṣùgbọ́n nísinsin yìí nínú Kristi Jesu ̀yin ó ti jìnà réré nígbà àtijọ́ ni a súnmọ́ tòsí, nípa ̀jẹ̀ Kristi.

Nítòótọ́, ìre àti àánú ni yóò máa tọ̀ lẹ́yìn

ọjọ́ ayé è mi gbogbo,

èmi yóò máa gbé inú ilé Olúwa

títí láéláé.

A presença que nunca abandona

Deus promete nunca nos deixar. Ele permanece fiel, está conosco em todo tempo e envia o Espírito para habitar em nossos corações.

Èmi fi yín sílẹ̀ láìní Olùtùnú, ma dàbí ọmọ òbí. Rárá o! Mo tún ń tọ̀ yín bọ̀.

Olúwa Ọlọ́run wa ó pẹ̀wa ó ti pẹ̀àwọn baba wa; ó ṣe fi sílẹ̀ tàbí kọ̀ sílẹ̀.

Ṣùgbọ́n nínú ̀pọ̀ àánú rẹ, ìwọ òpin wọn tàbí kọ̀ wọ́n sílẹ̀, nítorí ìwọ ni Ọlọ́run olóore-ọ̀fẹ́ àti aláàánú.

Ìkíni ìkẹyìn

Ǹjẹ́ Olúwa àlàáfíà, fúnra rẹ̀ máa fún yín àlàáfíà nígbà gbogbo. Olúwa ó pẹ̀gbogbo yín.

Ìkíni ìkẹyìn

àkótán, ará ó gbòóṣe, ṣe àtúnṣe ̀yín, tújúká, jẹ́ onínú kan, máa àlàáfíà, Ọlọ́run ìfẹ́ àti ti àlàáfíà yóò pẹ̀yín.

Nípa èyí ni àwa mọ̀ àwa ń gbé inú rẹ̀, àti Òun nínú wa, nítorí ó ti fi ̀rẹ̀ fún wa.

ẹni ó Ọlọ́run , ṣe òun nìkan, àní ọmọ rẹ̀ kan ṣoṣo, ẹni òun pàápàá jẹ́ Ọlọ́run, ó ìbáṣepọ̀ ó súnmọ́ jùlọ pẹ̀baba, òun náà ni ó fi í hàn.

Mose níbẹ̀ pẹ̀Olúwa fún ogójì ̀sán àti ogójì òru láìjẹ oúnjẹ tàbí mu omi. Ó kọ ̀rọ̀ májẹ̀náà òfin mẹ́wàá sára wàláà.

àwọn aláìsàn ń bẹ nínú rẹ̀ láradá, fún wọn , Ìjọba Ọlọ́run dẹ̀dẹ̀ yín!

Àtúnṣe asà

̀Ọlọ́run sórí Asariah ọmọ Odedi. Ó jáde lọ Asa, ó fún un , "Tẹ́si mi Asa, àti gbogbo Juda àti Benjamini. Olúwa pẹ̀rẹ, nígbà ìwọ pẹ̀rẹ̀. Ti ìwọ a, ìwọ yóò i ̀̀dọ̀ rẹ ṣùgbọ́n ìwọ kọ̀ ́ sílẹ̀, òun yóò kọ̀ ́ sílẹ̀. Fún ọjọ́ pípẹ́ ni Israẹli ti láì sin Ọlọ́run òtítọ́, àti láìní àlùfáà ti ń kọ́ ni, àti láìní òfin. Ṣùgbọ́n nínú ìpọ́njú wọn, wọ́n padà si Olúwa Ọlọ́run Israẹli, wọ́n wa kiri. Wọ́n ri i ̀gbẹ́ wọn. ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì ó léwu ènìyàn máa rìn ìrìnàjò kiri, nítorí gbogbo àwọn olùgbé ilẹ̀ náà nínú làálàá ńlá. Orílẹ̀-èdè kan ń run èkejì àti ìlú kan òmíràn nítorí Ọlọ́run ń yọ wọ́n lẹ́nu pẹ̀oríṣìíríṣìí ìpọ́njú. Ṣùgbọ́n fun ìwọ, jẹ́ alágbára, ó ṣe ṣàárẹ̀. Nítorí a ó fi èrè iṣẹ́ ̀ rẹ."

Nígbà Asa gbọ́ ̀rọ̀ wọ̀nyí àti àsọtẹ́lẹ̀ Asariah ọmọ Odedi wòlíì, ó àyà rẹ̀ le. Ó gbogbo ohun ìríra kúrò gbogbo ilẹ̀ Juda àti Benjamini àti kúrò nínú àwọn ìlú ó ti fi agbára orí òkè Efraimu. Ó tún pẹpẹ Olúwa ṣe ó iwájú portiko ti ilé Olúwa.

Nígbà náà, ó pe gbogbo Juda àti Benjamini jọ àti àwọn ènìyàn láti Efraimu, Manase àti Simeoni ó ti ṣe àtìpó àárín wọn. Nítorí ̀pọ̀ ènìyàn ti ̀dọ̀ rẹ̀ láti Israẹli nígbà wọ́n i Olúwa Ọlọ́run rẹ̀ pẹ̀rẹ̀.

Wọ́n péjọ Jerusalẹmu oṣù kẹta ọdún kẹ́̀dógún ti ìjọba Asa. àkókò yìí, wọ́n ẹbọ Olúwa ̀́dẹ́gbẹ̀rin (700) akọ màlúù àti ̀́dẹ́gbàárin (7,000) àgùntàn àti àwọn ewúrẹ́ láti ibi ìkógun wọ́n ti padà. Wọ́n tún májẹ̀láti Olúwa Ọlọ́run àwọn baba wọn tinútinú wọn àti tọkàntọkàn wọn. ẹnikẹ́ni Olúwa Ọlọ́run Israẹli, pípa ni á ó pa á láti ẹni kékeré orí ẹni ńlá àti ọkùnrin àti obìnrin. Wọ́n búra ohùn rara fún Olúwa àti pẹ̀ìhó ńlá àti pẹ̀ìpè àti pẹ̀fèrè. Gbogbo Juda yọ̀ nípa ìbúra náà nítorí wọ́n ti búra tinútinú wọn wọ́n fi gbogbo ìfẹ́ inú wọn a, wọ́n i, Olúwa fún wọn ìsinmi káàkiri.

Ọba Asa Maaka ìyá ńlá rẹ̀ kúrò láti máa ṣe ayaba, nítorí ó ère kan fún Aṣerah òrìṣà rẹ̀. Asa ère náà lulẹ̀, ó o àfonífojì Kidironi. Ṣùgbọ́n a àwọn ibi gíga náà kúrò Israẹli; síbẹ̀síbẹ̀ ọkàn Asa pípé ọjọ́ rẹ̀ gbogbo. Ó àwọn ohun mímọ́ náà ti baba rẹ̀ àti àwọn ohun mímọ́ ti òun tìkára rẹ̀ tirẹ̀ sínú ilé Ọlọ́run, wúrà àti fàdákà àti àwọn ohun èlò náà.

ogun mọ́ títí fún ọdún márùndínlógójì ti ìjọba Asa.

Seja o primeiro

Este artigo te tocou? Faça uma oração!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.