Pular para o conteúdo
Publicidade

Raiva

Por Bíblia Online

A raiva é uma emoção humana que a Bíblia trata com seriedade. Irar-se não é pecado em si, mas a ira descontrolada destrói relacionamentos e abre porta para o mal.

Controlar a ira

A Bíblia nos exorta a ser tardios para irar-se. A resposta branda desvia o furor, e o que se controla é mais forte que um guerreiro.

Gbígbọ́ àti ṣíṣe ọrọ̀ náà

mọ èyí, ̀yin ará mi olùfẹ́; jẹ́ olúkúlùkù ènìyàn ó máa yára láti gbọ́, ó lọ́ra láti fọhùn, ó si lọ́ra láti bínú;

Ìdáhùn pẹ̀lẹ́ ìbínú padà

ṣùgbọ́n ̀rọ̀ líle máa ń ru ìbínú sókè.

Onísùúrù ènìyàn òye ó pọ̀,

ṣùgbọ́n onínú-fùfù ènìyàn máa ń fi ìwà aṣiwèrè hàn.

Aláìgbọ́n ènìyàn fi gbogbo ẹnu rẹ̀ bínú

ṣùgbọ́n ọlọ́gbọ́n ènìyàn a máa ìbínú rẹ̀ ìjánu.

Aláìgbọ́n ènìyàn fi ìbínú un rẹ̀ hàn lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀,

ṣùgbọ́n olóye ènìyàn fojú fo ìyànjẹ.

Irar-se sem pecar

Paulo ensina: irai-vos, mas não pequeis. Não deixe o sol se pôr sobre a vossa ira, para não dar lugar ao diabo.

Nínú ìbínú yín, máa ṣe ṣẹ̀, ṣe jẹ́ oòrùn wọ̀ ìbínú yín, bẹ́̀ ni ṣe fi ààyè ̀gbẹ́ kan fún Èṣù.

Iyì ni ó jẹ́ fún ènìyàn láti fún ìjà,

ṣùgbọ́n gbogbo aláìgbọ́n a máa tètè ìjà.

Ìgbéraga máa ń ìjà sílẹ̀ ni

ṣùgbọ́n ọgbọ́n nínú àwọn ń gba ìmọ̀ràn.

Amor e perdão acima da raiva

O amor cobre multidão de pecados. A Bíblia nos chama a não alimentar rancor, mas a perdoar e amar, vencendo a raiva com compaixão.

Ìríra a máa ìjà sílẹ̀,

ṣùgbọ́n ìfẹ́ a máa bo gbogbo àṣìṣe mọ́lẹ̀.

Ìfẹ́ a máa sùúrù, ìfẹ́ a máa ṣeun, ìfẹ́ í ṣe ìlara, ìfẹ́ í fẹ̀, ìfẹ́ í sọ̀rọ̀ ìgbéraga. Ìfẹ́ í hùwà àìtọ́, í ohun ara rẹ̀ nìkan. Ìfẹ́ í bínú fùfù, ìfẹ́ í fi búburú ọmọ ẹnìkejì sínú.

" Ìwọ gbọdọ̀ kórìíra arákùnrin rẹ lọ́kàn rẹ, aládùúgbò rẹ , o ba à jẹ́ alábápín nínú ̀bi rẹ̀.

" Ìwọ gbọdọ̀ gbẹ̀san: ṣe bínú èyíkéyìí nínú àwọn ènìyàn rẹ. Ṣùgbọ́n, ìwọ ó fẹ́ ẹnìkejì rẹ ara rẹ. Èmi ni Olúwa.

Nígbà náà, ó fi kún un , "Èyí ti ó ti ọkàn ènìyàn jáde ni ń sọ ni di aláìmọ́. Nítorí láti inú ọkàn ènìyàn ni àwọn èrò búburú wọ̀nyí ti ń jáde : àgbèrè, olè, ìpànìyàn, panṣágà, ̀kánjúwà, odì yíyàn, ìtànjẹ, ìmọ-tara-ẹni, ìlara, ̀rọ̀ ̀yìn, ìgbéraga, òmùgọ̀. Gbogbo àwọn nǹkan búburú wọ̀nyí ń inú , àwọn ń sọ yín di aláìmọ́."

kíyèsára, ará, ọkàn búburú ti àìgbàgbọ́ ṣe nínú ẹnikẹ́ni yín, lílọ kúrò lọ́dọ̀ Ọlọ́run alààyè.

"ọkùnrin kan kọ ìyàwó rẹ̀ sílẹ̀

obìnrin náà lọ fẹ́ ọkọ mìíràn,

ǹjẹ́ ọkùnrin náà tún tọ̀ ́ ?

Ǹjẹ́ ilẹ̀ náà di aláìmọ́ ?

Ṣùgbọ́n ìwọ ti gbé pẹ̀onírúurú panṣágà gẹ́gẹ́ olùfẹ́,

ṣé ìwọ yóò tún padà sọ́dọ̀ mi ?"

ni Olúwa .

"Gbé ojú rẹ sókè ibi gíga wọ̀n-ọn-nì,

o ó ibi kan ha a ́ jẹ́?

ojú ̀, ìwọ jókòó de àwọn olólùfẹ́,

i ará Arabia kan nínú aginjù,

ìwọ ti ba ilẹ̀ náà jẹ́

pẹ̀ìwà àgbèrè àti ìwà búburú rẹ.

Nítorí náà, a ti fa ̀wààrà òjò sẹ́yìn,

ṣí òjò àrọ̀kúrò.

Síbẹ̀ ìwọ ojú líle ti panṣágà,

ìwọ kọ̀ láti ìtìjú.

Ǹjẹ́ ìwọ ha a láìpẹ́ yìí ,

Baba mi, ìwọ ̀rẹ́ mi láti ìgbà èwe mi.

Ìwọ yóò ha máa bínú títí?

Ìbínú rẹ yóò ha máa lọ títí láé?

Báyìí ni o ṣe ń sọ̀rọ̀

ìwọ ṣe gbogbo ibi ìwọ le ṣe."

Israẹli aláìṣòótọ́

àkókò ìjọba Josiah ọba, Olúwa fún mi , "Ṣé o ti nǹkan àwọn Israẹli aláìnígbàgbọ́ ti ṣe? Wọ́n ti lọ àwọn òkè gíga àti abẹ́ àwọn igi, wọ́n ti ṣe àgbèrè níbẹ̀. Mo nígbà wọ́n ti ṣe èyí wọn yóò padà, wọn padà, Juda aláìgbàgbọ́ arábìnrin rẹ̀ náà i. Mo fún Israẹli aláìnígbàgbọ́ ìwé ìkọ̀sílẹ̀, mo wọn kúrò nítorí gbogbo àgbèrè wọn. Síbẹ̀ mo Juda ó jẹ́ arábìnrin rẹ̀ bẹ̀, òun náà jáde lọ láti lọ ṣe àgbèrè. Nítorí ìwà èérí Israẹli jọ ́ lójú, ó ti ba ilẹ̀ jẹ́, ó ti ṣe àgbèrè pẹ̀òkúta àti igi. Látàrí gbogbo nǹkan wọ̀nyí Juda arábìnrin rẹ̀ aláìgbàgbọ́ padà tọ̀ pẹ̀gbogbo ọkàn rẹ̀, ṣe nípa fífarahàn olóòtítọ́," ni Olúwa .

Olúwa fún mi , "Israẹli aláìnígbàgbọ́ ṣe òdodo ju Juda ó ìgbàgbọ́ lọ. Lọ polongo ̀rọ̀ náà, lọ ìhà àríwá:

" Yípadà, Israẹli aláìnígbàgbọ́,’ ni Olúwa .

Ojú mi yóò korò mọ́,

nítorí mo jẹ́ aláàánú, ni Olúwa .

Èmi yóò bínú mọ́ títí láé.

à ti mọ ̀bi rẹ,

ìwọ ti ṣọ̀tẹ̀ Olúwa Ọlọ́run rẹ,

ìwọ ti ojúrere rẹ lọ́dọ̀ ọlọ́run àjèjì

lábẹ́ gbogbo igikígi ó gbilẹ̀,

̀yin gba ohun mi gbọ́,’ "

ni Olúwa .

"Padà, ̀yin ènìyàn aláìnígbàgbọ́," ni Olúwa , "nítorí èmi ni ọkọ rẹ. Èmi ó yàn ́, ̀kan láti ìlú àti méjì láti ̀. Èmi ó Sioni. Lẹ́yìn èyí, èmi ó fún àwọn olùṣọ́-àgùntàn láti inú ọkàn mi, wọn yóò ṣáájú yín pẹ̀òye àti ìmọ̀. ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì, ̀yin pọ̀ i lórí ilẹ̀ náà," ni Olúwa , "àwọn ènìyàn tún sọ , Àpótí ̀Olúwa.ìrántí wọn mọ́, a yóò pàdánù rẹ̀, bẹ́̀ ni a yóò tún kan òmíràn mọ́. ìgbà náà, wọn yóò pe Jerusalẹmu ìtẹ́ Olúwa gbogbo orílẹ̀-èdè yóò péjọ Jerusalẹmu láti bọ̀wọ̀ fún orúkọ Olúwa, wọn yóò tún tẹ̀àyà líle búburú wọn mọ́. ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì ni ilé Juda yóò darapọ̀ mọ́ ilé Israẹli. Wọn yóò láti ilẹ̀ àríwá ilẹ̀ mo fi fún àwọn baba ńlá yín gẹ́gẹ́ ilẹ̀ ìní.

"Èmi fúnra mi sọ ,

" Báwo ni inú mi yóò ti dùn ,

èmi ó tọ́ ọmọkùnrin

n fún ilẹ̀ ó .

Mo ìwọ yóò Baba mi

o ṣàì tọ̀ lẹ́yìn.

Ṣùgbọ́n gẹ́gẹ́ aláìgbàgbọ́ obìnrin ọkọ rẹ̀,

bẹ́̀ gẹ́gẹ́ o jẹ́ aláìgbàgbọ́ mi. Ìwọ ilé Israẹli,"

ni Olúwa .

A gbọ́ ohùn àgàn láti ibi gíga,

ẹkún àti ̀bẹ̀ àwọn ọmọ Israẹli,

nítorí wọ́n ti ̀wọn po,

wọ́n ti gbàgbé Olúwa Ọlọ́run wọn.

"Padà, ̀yin ènìyàn aláìnígbàgbọ́,

Èmi ó wo ìpadàsẹ́yìn kúrò ̀títọ́ rẹ sàn."

"Bẹ́̀, ni a ó sọ́dọ̀ rẹ

nítorí ìwọ ni Olúwa Ọlọ́run wa.

Nítòótọ́, asán ni ìbọ̀rìṣà àti ìrúkèrúdò ó àwọn orí òkè

kéékèèké àti àwọn òkè gíga,

nítòótọ́, nínú Olúwa Ọlọ́run

wa ni ìgbàlà Israẹli .

Láti ìgbà èwe wa ni àwọn òrìṣà ìtìjú ti

jẹ èso iṣẹ́ àwọn baba wa run,

̀wọ́ ẹran wọn àti agbo ẹran wọn,

ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin wọn.

Jẹ́ a dùbúlẹ̀ nínú ìtìjú wa,

ìtìjú wa mọ́lẹ̀.

A ti ṣẹ̀ Olúwa Ọlọ́run wa,

àwa àti àwọn baba wa,

láti ìgbà èwe wa títí di òní

a gbọ́rọ̀ Olúwa Ọlọ́run wa."

Luciano Januzelli
1 pessoa deu Amém