Publicidade

Levítico 19

Àwọn onírúurú òfin

1 Olúwa sọ fún Mose , 2 19.2: Le 11.44,45; 20.7,26; 1Pt 1.16."gbogbo àpéjọpọ̀ àwọn ọmọ Israẹli sọ̀rọ̀, fún wọn , jẹ́ mímọ́ nítorí Èmi Olúwa Ọlọ́run yín jẹ́ mímọ́.

3 19.3,30: Ek 20.12; De 5.16; Ek 20.8; 23.12; 34.21; 35.23; De 5.12-15. " Ẹnìkọ̀̀kan yín gbọdọ̀ bọ̀wọ̀ fún ìyá àti baba rẹ̀, ya ọjọ́ ìsinmi mi mímọ́. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.

4 19.4: Ek 20.4; Le 26.1; De 4.15-19; 27.15. " ṣe yípadà tọ ère òrìṣà lẹ́yìn, bẹ́̀ ni gbọdọ̀ rọ ère òrìṣà idẹ fún ara yín. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.

5 " Nígbà ̀yin ẹbọ àlàáfíà Olúwa, ̀yin ó ṣe é ̀yóò fi jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà dípò yín. 6 ọjọ́ u náà ni gbọdọ̀ jẹ ́ tàbí ọjọ́ kejì; èyí ó ṣẹ́di ọjọ́ kẹta ni fi iná sun. 7 jẹ nínú èyí ó ṣẹ́di ọjọ́ kẹta, àìmọ́ ni èyí jẹ́, jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà. 8 Nítorí náà ẹnikẹ́ni ó jẹ ́ ni a ó di ̀bi rẹ̀ , nítorí ó ti ba ohun mímọ́ Olúwa jẹ́, irú ẹni bẹ́̀ ni kúrò láàrín àwọn ènìyàn rẹ̀.

9 19.9,10: Le 23.22; De 24.20,21. " Nígbà ̀yin kórè nǹkan oko yín, ̀yin ó fi díẹ̀ sílẹ̀ láìkórè àwọn igun oko yín, ̀yin gbọdọ̀ ṣa ̀ṣẹ́ (nǹkan oko ti gbàgbé tàbí ó bọ́ sílẹ̀). 10 ̀yin gbọdọ̀ kórè oko yín tan pátápátá, bẹ́̀ ni ̀yin gbọdọ̀ ṣa èso ó rẹ̀ bọ́ sílẹ̀ nínú ọgbà àjàrà yín. fi wọ́n sílẹ̀ fún àwọn aláìní àti fún àwọn àlejò. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.

11 19.11: Ek 20.15,16; De 5.19. " Ìwọ gbọdọ̀ jalè.

" Ìwọ gbọdọ̀ parọ́.

" gbọdọ̀ tan ara yín jẹ.

12 19.12: Ek 20.7; De 5.11; Mt 5.33. " Ìwọ gbọdọ̀ fi orúkọ mi búra èké, o tipa bẹ́̀ ba orúkọ Ọlọ́run rẹ jẹ́. Èmi ni Olúwa.

13 19.13: De 24.15; Jk 5.4. " Ìwọ gbọdọ̀ rẹ́ aládùúgbò rẹ jẹ bẹ́̀ ni ìwọ gbọdọ̀ á lólè.

" Ìwọ gbọdọ̀ owó iṣẹ́ alágbàṣe dúró di ọjọ́ kejì.

14 19.14: De 27.18. " Ìwọ gbọdọ̀ ṣépè adití, bẹ́̀ ni o gbọdọ̀ fi ohun ìdìgbòlù iwájú afọ́, ṣùgbọ́n bẹ̀Ọlọ́run rẹ. Èmi ni Olúwa.

15 19.15: Ek 23.6; De 1.17. " Ìwọ gbọdọ̀ ìdájọ́ po, ṣe ojúsàájú ẹjọ́ tálákà, bẹ́̀ ni o gbọdọ̀ gbé ti ọlọ́lẹ́yìn, ṣùgbọ́n fi òdodo ṣe ìdájọ́, àwọn aládùúgbò rẹ.

16 " Ìwọ gbọdọ̀ máa ṣèyíṣọ̀hún olóòfófó láàrín àwọn ènìyàn rẹ.

" Ìwọ gbọdọ̀ ṣe ohunkóhun yóò fi ̀aládùúgbò rẹ wéwu. Èmi ni Olúwa.

17 " Ìwọ gbọdọ̀ kórìíra arákùnrin rẹ lọ́kàn rẹ, aládùúgbò rẹ , o ba à jẹ́ alábápín nínú ̀bi rẹ̀.

18 19.18: Mt 5.43; 19.19; 22.39; Mk 12.31; Lk 10.27; Ro 13.9; Ga 5.14; Jk 2.8. " Ìwọ gbọdọ̀ gbẹ̀san: ṣe bínú èyíkéyìí nínú àwọn ènìyàn rẹ. Ṣùgbọ́n, ìwọ ó fẹ́ ẹnìkejì rẹ ara rẹ. Èmi ni Olúwa.

19 19.19: De 22.9,11. " Máa pa àṣẹ mi mọ́.

" Ìwọ gbọdọ̀ jẹ́ ohun ̀sìn rẹ máa gùn pẹ̀̀mìíràn.

" Ìwọ gbọdọ̀ gbin dàrúdàpọ̀ oríṣìí irúgbìn méjì sínú oko kan.

" Ìwọ gbọdọ̀ wọ aṣọ èyí a fi oríṣìí ohun èlò ìhunṣọ méjì ṣe.

20 " ọkùnrin kan obìnrin ó jẹ́ ẹrú lòpọ̀, ẹni a ti mọ̀ pọ̀ pẹ̀ọkùnrin mìíràn a ì á padà tàbí sọ ́ di òmìnira. gbọdọ̀ ṣe ìwádìí jẹ wọ́n ìyà tọ́ ṣùgbọ́n gbọdọ̀ pa wọ́n, torí ì ì di òmìnira. 21 ọkùnrin náà àgbò kan ẹnu-ọ̀àgọ́ ìpàdé i ẹbọ ̀bi Olúwa. 22 Àlùfáà yóò ṣe ètùtù fún un, pẹ̀àgbò ẹbọ ̀bi náà níwájú Olúwa fún ìdáríjì ̀ṣẹ̀ ó ti ṣẹ̀. A ó dárí ̀ṣẹ̀ náà í.

23 " Nígbà ilẹ̀ náà gbin igi eléso, èso wọn ohun èèwọ̀. Fún ọdún mẹ́ta ni á èèwọ̀, gbọdọ̀ jẹ ́. 24 Ṣùgbọ́n ọdún kẹrin, gbogbo èso wọ̀nyí yóò jẹ́ mímọ́, ọrẹ fún ìyìn Olúwa. 25 ọdún karùn-ún ni ̀yin jẹ nínú èso igi náà, èso wọn ba à le máa pọ̀ i. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.

26 19.26: Le 3.17; 7.26,27; 17.10-16; De 12.16,23-25; 18.10. " ṣe jẹ ẹrankẹ́ran pẹ̀̀jẹ̀ rẹ̀.

" gbọdọ̀ lọ ̀dọ̀ yẹ̀míwò tàbí oṣó.

27 19.27: Le 21.5; De 14.1. " ṣe òṣù àárín orí yín (fífá irun ̀gbẹ́ orí, a ó irun àárín orí ) tàbí orí irùngbọ̀n yín àwọn aláìkọlà ti ń ṣe.

28 " ṣe tìtorí òkú, ibi kankan nínú ̀ara yín, gbọdọ̀ sín gbẹ́rẹ́ kankan. Èmi ni Olúwa.

29 19.29: De 23.17,18. " ṣe ba ọmọbìnrin yín jẹ́ láti sọ ́ di panṣágà, ilẹ̀ yín ba à di ti àgbèrè, ó kún fún ìwà búburú.

30 19.30: Ek 20.8-11; 23.12; 34.21; 35.2,3; Le 19.3; 26.2; De 5.12-15. " gbọdọ̀ máa pa ìsinmi mi mọ́ fi ̀wọ̀ fún ibi mímọ́ mi. Èmi ni Olúwa.

31 19.31: Le 20.6,27. " ṣe tọ abókùúsọ̀rọ̀ tàbí àwọn àjẹ́ lọ, gbọdọ̀ tọ̀ wọ́n lẹ́yìn láti jẹ́ wọ́n sọ yín di aláìmọ́. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.

32 " Fi ̀wọ̀ fún ọjọ́ orí arúgbó, bu ọlá fún àwọn àgbàlagbà bẹ̀Ọlọ́run yín. Èmi ni Olúwa.

33 19.33: Ek 22.21. " Nígbà àjèjì kan ń gbé pẹ̀yín ilẹ̀ yín, ṣe ṣe é ibi 34 àjèjì ń gbé pẹ̀yín dàbí onílé láàrín yín fẹ́ràn rẹ̀ i ara yín, torí ̀yin ti jẹ́ àjèjì ilẹ̀ Ejibiti . Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.

35 19.35,36: De 25.13-16; Òw 20.10; El 45.10. " ṣe lo òsùwọ̀n èké, nígbà ń díwọ̀n yálà nípa òsùwọ̀n ̀, òsùwọ̀n ìwúwo tàbí òsùwọ̀n onínú. 36 jẹ́ olódodo pẹ̀àwọn òsùwọ̀n yín òsùwọ̀n ìtẹ̀wọ̀n, òsùwọ̀n wíwúwo, òsùwọ̀n ìyẹ̀fun àti òsùwọ̀n nǹkan olómi yín láti jẹ́ èyí èrú nínú. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín ó yín jáde láti ilẹ̀ Ejibiti.

37 " ó máa pa gbogbo àṣẹ àti òfin mi mọ́, ó máa ṣe wọ́n. Èmi ni Olúwa.’ "

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-