Pular para o conteúdo
Publicidade

Reino dos céus

Por Bíblia Online

O Reino dos Céus é comparado por Jesus a tesouros, sementes e redes. Através de parábolas, Ele revelou os mistérios de um Reino que já está entre nós, mas que se consumará na eternidade.

O valor incomparável do Reino

O Reino dos Céus é como um tesouro escondido ou uma pérola de grande valor. Quem o encontra, vende tudo para possuí-lo.

Òwe ìṣúra a fi pamọ́ sínú ilẹ̀ àti ohun ̀ṣọ́ olówó iyebíye

"Ìjọba ̀run dàbí ìṣúra kan a fi pamọ́ sínú oko. Nígbà ọkùnrin kan i ó tún fi í pamọ́. Nítorí ayọ̀ rẹ̀, ó ta gbogbo ohun ìní rẹ̀, ó ra oko náà.

"Bákan náà ni ìjọba ̀run dàbí oníṣòwò kan ó ń òkúta olówó iyebíye láti . Nígbà ó ̀kan ó ni iye lórí, ó lọ láti ta gbogbo ohun ìní rẹ̀ láti le á.

Òwe hóró musitadi àti ìwúkàrà

Jesu tún pa òwe mìíràn fún wọn: "Ìjọba ̀run dàbí èso hóró musitadi, èyí ọkùnrin kan ó gbìn sínú oko rẹ̀. ó tilẹ̀ jẹ́ èso ó kéré púpọ̀ láàrín èso rẹ̀, síbẹ̀ ó di ohun ̀gbìn ó tóbi jọjọ. Ó di igi bẹ́̀ àwọn ẹyẹ ojú ̀run , wọ́n fi ̀ka rẹ ṣe ibùgbé."

Ó tún pa òwe mìíràn fún wọn: "Ìjọba ̀run dàbí ìwúkàrà obìnrin kan ó mọ́ ìyẹ̀fun púpọ̀ títí gbogbo rẹ fi di wíwú."

Parábolas do Reino

Jesus ensinou sobre o Reino mediante parábolas que revelam seu crescimento, seu juízo e a separação final entre justos e injustos.

Òwe èpò àti alikama

Jesu tún pa òwe mìíràn fún wọn: "Ìjọba ̀run dàbí àgbẹ̀ kan ó gbin irúgbìn rere oko rẹ̀, ṣùgbọ́n òru ọjọ́ kan, nígbà ó sùn, ̀rẹ̀ oko náà ó gbin èpò sáàrín alikama, ó tirẹ̀ lọ. Nígbà alikama náà bẹ̀rẹ̀ dàgbà, ó so èso, nígbà náà ni èpò náà fi ara hàn.

"Àwọn ọmọ ̀dọ̀ àgbẹ̀ náà , wọ́n sọ fún un , ̀, irúgbìn rere kọ́ ni ìwọ ha gbìn oko rẹ ? Báwo ni èpò ṣe níbẹ̀ nígbà náà?

"Ó sọ fún wọn , ̀ni ó ṣe èyí.

"Àwọn ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀ tún i , Ǹjẹ́ ìwọ ha fẹ́ a fa èpò náà tu kúrò?

"Ó wọn lóhùn , Rárá, nítorí ̀yin ń tu èpò kúrò, ó tu alikama dànù pẹ̀rẹ̀. jẹ́ àwọn méjèèjì máa dàgbà pọ̀, títí di àsìkò ìkórè. Èmi yóò sọ fún àwọn olùkórè náà láti kọ́kọ́ ṣa àwọn èpò kúrò wọ́n dìwọ́n ìtí, a sun wọn, wọ́n alikama sínú àká mi.’ "

Àlàyé òwe èpò àti alikama

Lẹ́yìn náà ó fi ̀pọ̀ ènìyàn sílẹ̀ lóde, ó wọ ilé lọ. Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ tọ̀ ́ , wọn , "Ṣàlàyé òwe èpò inú oko fún wa."

Ó wọn lóhùn , "Ọmọ Ènìyàn ni ẹni ó ń fúnrúgbìn rere. Ayé ni oko náà; irúgbìn rere ni àwọn ènìyàn ti ìjọba ̀run. Èpò ni àwọn ènìyàn wọ́n jẹ́ ti èṣù, ̀ó gbin àwọn èpò sáàrín alikama ni èṣù. Ìkórè ni òpin ayé, àwọn olùkórè àwọn angẹli.

"Gẹ́gẹ́ a ti èpò jọ, a sun ún nínú iná, bẹ́̀ gẹ́gẹ́ ni yóò ìgbẹ̀yìn ayé. Ọmọ Ènìyàn yóò ran àwọn angẹli rẹ̀, wọn yóò gbogbo ohun ń ni dẹ́ṣẹ̀ kúrò ìjọba rẹ̀ àti gbogbo ènìyàn búburú. Wọn yóò sọ wọ́n inú iná ìléru, níbi ti ẹkún òun ìpayínkeke yóò gbé . Nígbà náà ni àwọn olódodo yóò máa ràn oòrùn ìjọba Baba wọn. Ẹni ó létí, jẹ́ ó gbọ́.

Òwe ti àwọ̀n ẹja

"Bákan náà, a tún fi ìjọba ̀run àwọ̀n kan a sínú odò, ó onírúurú ẹja. Nígbà àwọ̀n náà kún, àwọn apẹja á sókè etí bèbè Òkun, wọ́n jókòó, wọ́n ṣa àwọn èyí ó dára sínú apẹ̀rẹ̀, ṣùgbọ́n wọ́n da àwọn dára . Bẹ́̀ gẹ́gẹ́ ni yóò ìgbẹ̀yìn ayé. Àwọn angẹli yóò láti ya àwọn ènìyàn búburú kúrò lára àwọn olódodo. Wọn ó ju àwọn ènìyàn búburú sínú iná ìléru náà, ibi ti ẹkún àti ìpayínkeke yóò gbé ."

Quem herda o Reino

Os humildes, os pobres de espírito e as crianças são herdeiros do Reino. Mas é difícil para os ricos entrarem nele.

"Alábùkún fún ni àwọn òtòṣì ̀,

nítorí tiwọn ni ìjọba ̀run.

Alábùkún fún ni àwọn ń ṣọ̀fọ̀,

nítorí a ó wọ́n nínú.

Alábùkún fún ni àwọn ọlọ́kàn tútù,

nítorí wọn yóò jogún ayé.

Alábùkún fún ni àwọn ebi ń pa

òǹgbẹ ń gbẹ́ nítorí òdodo, nítorí wọn yóò .

Alábùkún fún ni àwọn aláàánú,

nítorí wọn yóò àánú gbà.

Alábùkún fún ni àwọn ọlọ́kàn mímọ́,

nítorí wọn yóò Ọlọ́run.

Alábùkún fún ni àwọn onílàjà,

nítorí ọmọ Ọlọ́run ni a ó máa wọ́n.

Alábùkún fún ni àwọn ẹni a ṣe inúnibíni ,

nítorí wọ́n jẹ́ olódodo

nítorí tiwọn ìjọba ̀run.

"Alábùkún fún ni ̀yin nígbà àwọn ènìyàn fi àbùkù kàn yín wọn ṣe inúnibíni yín, tiwọn fi ètè èké sọ̀rọ̀ búburú gbogbo yín nítorí mi. yọ̀, ̀yin fún ayọ̀, nítorí ńlá ni èrè yín ̀run, nítorí bẹ́̀ ni wọ́n ṣe ṣe inúnibíni àwọn wòlíì ń bẹ ṣáájú yín.

Ẹni ó tóbi ìjọba ̀run

àkókò náà ni àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Jesu tọ̀ ́ , wọ́n bi í léèrè , "Ta ni ẹni ti ó pọ̀ìjọba ̀run?"

Jesu pe ọmọ kékeré kan ̀dọ̀ ara rẹ̀. Ó un dúró láàrín wọn. Ó , "Lóòótọ́ ni mo fún yín, àfi ̀yin padà dàbí àwọn ọmọdé, ̀yin yóò wọ ìjọba ̀run. Nítorí náà, ẹni ó rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀ gẹ́gẹ́ ọmọdé yìí, ni yóò pọ̀ jùlọ ìjọba ̀run.

Ṣùgbọ́n Jesu dáhùn , "jẹ́ àwọn ọmọdé sọ́dọ̀ mi, ṣe wọn lẹ́kun, nítorí irú wọn ni ìjọba ̀run."

Nígbà náà, Jesu fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ , "Lóòótọ́ ni mo fún yín , ó ṣòro fún ọlọ́rọ̀ láti wọ ìjọba ̀run." Mo tún fún yín , "Ó rọrùn fún ìbákasẹ láti wọ ojú abẹ́rẹ́ fún ọlọ́rọ̀ láti wọ ìjọba Ọlọ́run."

Nígbà àwọn ọmọ-ẹ̀yìn gbọ́ èyí, ẹnu wọn gidigidi, wọ́n béèrè , "Ǹjẹ́ ta ni ó ha le ?"

Ṣùgbọ́n Jesu wọ́n, ó fún wọn , "Ènìyàn ni èyí ṣòro fún; ṣùgbọ́n fún Ọlọ́run ohun gbogbo ni ṣíṣe."

fi etí sílẹ̀, ̀yin ará mi olùfẹ́: Ọlọ́run ha ti yan àwọn tálákà ayé yìí láti jẹ́ ọlọ́rọ̀ nínú ìgbàgbọ́, àti ajogún ìjọba náà, ó ti ṣe ìlérí fún àwọn ó fẹ́ ?

Ṣùgbọ́n, ẹni mímọ́ ti ̀gá-ògo ni yóò gba ìjọba náà, yóò jogún un rẹ títí láé àti títí láéláé.

Buscar o Reino acima de tudo

Jesus ensinou que devemos buscar primeiro o Reino e sua justiça. Nem todo que diz 'Senhor, Senhor' entrará — só quem faz a vontade do Pai.

"í ṣe gbogbo ẹni ń , Olúwa, Olúwa,ni yóò wọ ìjọba ̀run, ṣe ẹni ń ṣe ìfẹ́ baba mi ń bẹ ̀run.

Ẹnikẹ́ni ti ó òfin ó tilẹ̀ kéré jùlọ, ó kọ́ ẹlòmíràn láti ṣe bẹ́̀, òun ni yóò kéré jùlọ ìjọba ̀run, ṣùgbọ́n ẹni ó ń ṣe wọ́n, ó ń kọ́ wọn, ni yóò jẹ́ ẹni ńlá ìjọba ̀run. Nítorí náà ni mo ti fún yín àfi òdodo yín ju ti àwọn Farisi àti ti àwọn olùkọ́ òfin lọ, dájúdájú ̀yin yóò le wọ ìjọba ̀run.

"Nítorí náà, báyìí ni ṣe máa gbàdúrà:

" Baba wa ń bẹ ̀run,

̀wọ̀ fún orúkọ yín,

ìjọba yín ,

ìfẹ́ tiyín ni a ṣe

ayé ti ̀run.

Johanu onítẹ̀bọmi tún ọnà náà ṣe

ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì, Johanu onítẹ̀bọmi , ó ń wàásù aginjù Judea. Ó ń , "ronúpìwàdà, nítorí ìjọba ̀run dẹ̀dẹ̀."

Láti ìgbà náà lọ ni Jesu ti bẹ̀rẹ̀ wàásù: "ronúpìwàdà, nítorí ìjọba ̀run dẹ̀dẹ̀."

̀yin ti ń lọ, máa wàásù yìí , Ìjọba ̀run dẹ̀dẹ̀.’

Mo fún yín, ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ni yóò ti ìhà ìlà-oòrùn àti ìhà ìwọ̀-oòrùn , wọ́n á Abrahamu àti Isaaki àti Jakọbu jẹun ìjọba ̀run.

Lóòótọ́ ni fún yín, nínú àwọn a nínú obìnrin, ẹni ó í dìde ó ga ju Johanu onítẹ̀bọmi lọ, síbẹ̀ ẹni ó kéré ìjọba ̀run ni ó pọ̀ú lọ. Láti ìgbà ọjọ́ Johanu onítẹ̀bọmi títí di àkókò yìí ni ìjọba ̀run ti di à fi agbára wọ̀, àwọn alágbára ń fi ipá gbà á.

A herança eterna

O Reino dos Céus é inabalável e eterno. Deus nos chama a fazer firme a nossa vocação e eleição para entrar nesse Reino.

Nítorí náà àwa ń gbà ilẹ̀ ọba ti a , jẹ́ a ọpẹ́ nípa èyí ti a fi máa sin Ọlọ́run ni ìtẹ́wọ́gbà pẹ̀̀wọ̀ àti ìbẹ̀rẹ̀. Nítorí , "Ọlọ́run wa, iná ti ń ni run ni."

Wọn yóò sọ ògo ìjọba rẹ

wọn yóò sọ̀rọ̀ agbára rẹ,

gbogbo ènìyàn le mọ iṣẹ́ agbára rẹ̀

àti ọláńlá ìjọba rẹ ó lógo.

Ìjọba rẹ ìjọba ayérayé ni,

àti ìjọba rẹ gbogbo ìrandíran.

Nítorí náà, ará túbọ̀ máa ṣe àìsimi láti sọ ìpè àti yíyàn yín di dájúdájú, nítorí ̀yin ń ṣe nǹkan wọ̀nyí, ̀yin yóò ṣubú. Nítorí báyìí ni a ó pèsè fún yín lọ́pọ̀lọ́pọ̀ láti wọ ìjọba àìnípẹ̀kun ti Olúwa àti Olùgbàlà wa Jesu Kristi.

Olúwa yóò yọ kúrò nínú iṣẹ́ búburú gbogbo, yóò mu inú ìjọba ̀run. Ẹni ti ògo fún láé àti láéláé. Àmín.

"bẹ̀, agbo kékeré, nítorí dídùn inú Baba yín ni láti fi ìjọba fún yín.

Nítorí ̀yin mọ èyí dájú , panṣágà, tàbí aláìmọ́ ènìyàn, tàbí wọ̀bìà (í ṣé abọ̀rìṣà), yóò ni ìpín kan ni ìjọba Kristi àti Ọlọ́run.

Seja o primeiro