Pular para o conteúdo
Publicidade

Relacionamentos

Por Bíblia Online

Os relacionamentos são centrais na vida cristã. A Bíblia orienta sobre amizade, casamento, família e convivência, sempre tendo o amor como fundamento de toda relação.

Amor e amizade

O amigo ama em todo tempo. A Bíblia valoriza amizades verdadeiras que edificam, fortalecem e desafiam ao crescimento mútuo.

̀rẹ́ a máa fẹ́ni nígbà gbogbo,

arákùnrin fún ìgbà ìpọ́njú.

irin ń pọ́n irin

bẹ́̀ ni ènìyàn kan ń pọ́n ẹlòmíràn .

Ẹni méjì sàn ju ẹnìkan,

nítorí wọ́n èrè rere fún làálàá wọn.

̀kan ṣubú lulẹ̀,

̀rẹ́ rẹ̀ le è ràn án lọ́wọ́ ó á sókè,

ṣùgbọ́n ìyọnu ni fún ọkùnrin náà ó ṣubú

ẹni ó le è ràn án lọ́wọ́!

ó tilẹ̀ jẹ́ , a le è kojú ogun ẹnìkan,

àwọn méjì le è gbìjà ara wọn,

ìkọ́ okùn mẹ́ta í dùn ún yára .

Casamento e família

O casamento é aliança sagrada. O marido deve amar a esposa como Cristo amou a Igreja, e ambos devem cultivar respeito e submissão mútua.

̀yin ọkọ, fẹ́ràn àwọn aya yín, gẹ́gẹ́ Kristi fẹ́ràn ìjọ, ó fi ara rẹ̀ fún un. òun sọ ́ di mímọ́ lẹ́yìn ó fi ̀rọ̀ wẹ̀ ́ nínú agbada omí.

Bẹ́̀ ó tọ́ àwọn ọkùnrin máa fẹ́ràn aya wọn gẹ́gẹ́ ara àwọn fúnra wọn.

Ṣùgbọ́n olúkúlùkù yín fẹ́ràn aya rẹ̀, bẹ́̀ gẹ́gẹ́ òun fúnra rẹ̀; aya ó bọ̀wọ̀ fún ọkọ rẹ̀.

̀yin aya, máa tẹríba fún àwọn ọkọ yín, gẹ́gẹ́ fún Olúwa. Nítorí ọkọ ni ó ń ṣe orí aya, gẹ́gẹ́ Kristi i ṣe orí ìjọ, òun si ń ṣe ara rẹ̀, Òun ni Olùgbàlà rẹ̀.

Àwọn òfin fún agbo ilé Kristi

̀yin aya, máa tẹríba fún àwọn ọkọ yín, gẹ́gẹ́ ó ti yẹ nínú Olúwa.

̀yin ọkọ, máa fẹ́ràn àwọn aya yín, ṣe korò wọn.

Olúwa Ọlọ́run , "dára ọkùnrin òun nìkan. Èmi yóò ṣe olùrànlọ́wọ́ ó i rẹ̀ fún un."

Ṣùgbọ́n nítorí àgbèrè pọ̀ bẹ́̀ gẹ́́ ọkùnrin kọ̀̀kan gbéyàwó tirẹ̀. Bẹ́̀ ni obìnrin kọ̀̀kan ọkọ tirẹ̀.

A máa ń jogún ilé àti ọrọ̀ lọ́dọ̀ òbí,

ṣùgbọ́n aya olóye láti ̀dọ̀ Olúwa ni.

Ta ni ó le aya oníwà rere?

Ó níye lórí ju iyùn lọ.

Gbogbo ara rẹ jẹ́ kìkì ẹwà, olólùfẹ́ mi;

ṣí àbàwọ́n lára rẹ.

Convivência saudável

Os relacionamentos florescem quando tratamos os outros como gostaríamos de ser tratados, com amor crescente e caráter maduro.

Nítorí náà, nínú gbogbo ohunkóhun ti ̀yin ń fẹ́ ènìyàn ó ṣe yín, bẹ́̀ ni ̀yin ó ṣe wọn gẹ́gẹ́; nítorí èyí ni òfin àti àwọn wòlíì.

bọ̀wọ̀ fún baba àti ìyá rẹ. o fẹ́ aládùúgbò rẹ gẹ́gẹ́ ara rẹ.’ "

A béèrè , Ọlọ́run ràn yín lọ́wọ́ bẹ́̀ ìfẹ́ yín yóò fi gbòòrò yóò sàn kan olúkúlùkù yín. Èyí yóò jẹ́ àpẹẹrẹ gẹ́gẹ́ ìfẹ́ àwa náà ṣe sàn kan ̀yin náà.

Ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni pèsè fún àwọn tirẹ̀, pàápàá fún àwọn ará ilé rẹ̀, ó ti sẹ́ ìgbàgbọ́, ó burú ju aláìgbàgbọ́ lọ.

ṣe dàpọ̀ pẹ̀àwọn aláìgbàgbọ́

ṣe fi àìdọ́gba dàpọ̀ pẹ̀àwọn aláìgbàgbọ́, nítorí ìdàpọ̀ kín ni òdodo pẹ̀àìṣòdodo? Ìdàpọ̀ kín ni ìmọ́lẹ̀ pẹ̀òkùnkùn?

Ǹjẹ́ nísinsin yìí, ènìyàn ni èmi ń ojúrere rẹ̀ tàbí Ọlọ́run? Tàbí ènìyàn ni èmi ń fẹ́ láti ? èmi ń fẹ́ láti wu ènìyàn, èmi jẹ́ ìránṣẹ́ Kristi.

Àti nítorí ìdí èyí, máa ṣe àìsimi gbogbo, fi ìwà rere kún ìgbàgbọ́, àti ìmọ̀ kún ìwà rere; àti àìrékọjá kún ìmọ̀; àti sùúrù kún àìrékọjá; àti ìwà-bí-Ọlọ́run kún sùúrù. Àti ìfẹ́ ọmọnìkejì kún ìwà-bí-Ọlọ́run; àti ìfẹ́ni kún ìfẹ́ ọmọnìkejì.

Orúkọ rere sàn ju ọrọ̀ lọ

Yíyan orúkọ rere sàn ju púpọ̀ ọrọ̀ lọ,

àti ojúrere dára ju fàdákà àti wúrà lọ.

Seja o primeiro